
Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Òkúdu 2026 ní 08:05:39
Agbekalẹ BBC Africa lori ogun abẹle Biafra, to ni i ṣe pẹlu gbajumọ adari orin lagbaaye, Meji Alabi

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Òkúdu 2026 ní 09:39:40
Ṣaaju ni ẹgbẹ NUT ti sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo wi pe ki wọn ṣe ifẹhonuhan lati beere fun itusilẹ awọn tawọn janduku agbebọn ji gbe.

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:27:18
A gbọ pe eeyan mẹjọ lo wa ni ẹsẹ kan aye ẹsẹ kan ọrun gẹgẹ bii ọrọ minisita fun ọrọ abẹle, Laurent Nuñez.

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:07:55
Makinde sọ fún gbogbo eeyan to wa nibi ipade naa to waye ni Esinele pe kí wọn ma foya torí ìjọba n ṣiṣẹ takun takun lati ri pe won doola awon t’awọn jàndùkú agbébọn ji gbe lọ.

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:27:37
Ọgagun Rabe Abubakar to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun Naijiriala larin ọdun 2015 si ọdun 2017 ni wọn ji gbe lasiko ti wọn kọlu ọkọ rẹ lasiko to n rinrinajo lọ si ipinlẹ Katsina.

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:44:54
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, Obarisa Ilorin Afonja, Oba Omobolaji Adifakawo Agbomola, sọ pe awọn agbara ti Afọnja fi jagun si wa sibẹ, awọn si le lo o lati sẹgun ijinigbe ati ipaniyan ti ijọba ba gba awọn laye.

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:17:04
Lẹyin ti agbofinro fi ọrọ wa awọn olukọ ati ọpọ akẹkọọ lẹnuwo, ti wọn si wo ẹrọ CCTV to wa nibẹ ni wọn fidi rẹ mulẹ pe akẹkọọ mẹjọ kan lo pilẹ iṣẹlẹ naa ti wọn si sọ ina sile ẹkọ ọhun.

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:42:38
Wọn ni eyii jẹ ọkan lara awọn ọna lati mu aye dẹrun fun awọn oṣiṣẹ naa latari bi ọrọ aje Naijiria ṣe le koko lonii.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:59:02
Ikede yii lo waye nibi eto idibo abẹlẹ ẹgbẹ oṣelu naa to waye ninu gbangan ọmọwe agba Theofilus Ogunlesi to wa ni adojuko ile iwosan UCH, nilu uIbadan.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 19:40:03
Awọn mọlẹbi oloogbe naa lo kede iroyin iku rẹ ninu atẹjade kan lọjọ Abamẹta.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:03:30
Ofin tuntun ọhun tun ke pe araalu lati fi to ijọba leti ti wọn ba kofiri ẹnikẹni to ba n ṣe nnkan naa ti wọn ti fofin de.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:20:02
Ṣaaju eto ayeye ọdun ọhun to waye lọjọ Ẹti, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Karun-un ti a wa yii, ni oniruuru awuyewuye ti n waye lori boya eto naa ko ni waye lọdun yii.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:34:49
Awọn olukọ naa bẹrẹ iwọde wọn lati agbegbe Iwo road niluu Ibadan ti wọn si gba Idi-ape, Gate titi de ọfiisi ijọba Ipinlẹ Oyo ni Agodi niluu ibadan.

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:56:41
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:53:19
Itan igbe aye Balogun Bello Kuku, ẹni to mu Islam wọ ilẹ Ijẹbu, to si tun bẹrẹ ayẹyẹ ọdun Ojude Oba to di gbaju-gbaja ni Ijebu Ode.

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:53:09
Lọdọọdun ni ọpọ eeyan maa n ti ara wọn, koda wọn maa n tẹ awọn mii mọlẹ nibẹ lati ri pe awọn lanfaani lati fọwọ kan okuta naa.

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:26:49
Bi AI ṣe wulo lati mu iṣẹ ya kankan, bẹẹ naa ni awọn to mọ lilo rẹ nidakeji tun maa n lo o lati ya fidio eeyan tabi lo ohùn ẹnu ẹni ti wọn ba fẹ fi ṣe jamba fun.

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:19:43
BBC News Yorùbá ṣe wọ inú ìtàn lọ, láti ṣe ilanilọyẹ lórí ohun tó fà á, tí ìran Yoruba ṣe ń kọ ila àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun.

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:56:49
Nigba to n sọrọ, Mercy ni oun kọ loun ran aṣọ naa, bi ko ṣe gbajumọ aranṣọ Toyin Lawani to jẹ ọga ileeṣẹ Tianah Empire.

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:15:58
Ajọ IRGC ni oun ṣekọlu si ibudo naa lẹyin ti Amẹrika yin ado oloro si ẹkun guusu Iran.

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:52:55
Ninu ọsẹ yii naa ni ọrọ fọnran ohun ti wọn fi AI gbe jade bọ sori ayelujara, nibi ti wọn ti fi ohùn ẹnu Tinubu sọ awọn ọrọ to n tako araalu, to si le da rugudu silẹ.

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:32:10
Aarẹ Bola Tinubu ni yiyọ owo iranwọ ori epo, riro owo naira lagbara lọja agbaye ati gbigbe ogun ti aabo to mẹhẹ ti oun dawọle, ti so eso rere.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:01:28
Ọga ile ẹkọ to sọrọ ninu fidio tawọn ajinigbe fi sori ayelujara ni ‘‘a wa ninu otutu, a wa ninu ojo ati ninu oorun, awa atawọn ọmọ kekere ni a wa nibi. Ẹ jọwọ, a n bẹ yin.”

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:40:56
Ọlọpaa orukọ awọn ọlọpaa meji ti ọrọ naa kan lede gẹgẹ bii Kehinde ati Tobi lai mẹnuba orukọ wọn keji.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:06:51
BBC News Yoruba ba Amofin Azeem Gbolarumi sọrọ ni kete to wọle ibo abẹle PDP bii oludije gomina fẹgbẹ PDP nipinlẹ Oyo.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:46:23
Ọjọ Arafa ni ọjọ kẹsan oṣu Zul-Hijjah, ni onka oṣù ojú ọrun, tii se ọjọ Arafa.

Ọjọ́ Ajé, 25 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:03:04
Ana ode yiii ti I ṣe ọjọ Aiku, ọjọ kẹrinlelogun oṣu Karun-un ọdun 2026, ni igun tuntun yi tu igbimọ amuṣẹṣe ‘National working committee’ (NWC) ti David Mark n dari ka, ti wọn si yan Dumebi Kachikwu lẹyẹ o-sọka.

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:33:23
Awọn eeyan to sunmọ ọba Akanbi, ti wọn si mọ awọn ohun to ṣẹlẹ nipa awọn oju oori yii ti n ṣe alaye tiwọn.

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:03:47
NEMA ni kawọn to ba n gbe ni bebe okun lagbegbe naa tete fi ibẹ silẹ

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:26:10
Ṣaaju eto idibo naa ni ọkan lara awọn oludije ninu mẹta sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu Accord, Fatai Owoseni, juwọ silẹ pe oun ko dije mọ.

Ọjọ́ Àìkú, 24 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 17:03:20
Sẹnẹtọ Pius Anyim lo kede esi ibo naa lonii ọjọ Aiku ọjọ kẹrinlelogun oṣu Karun un yii.

Ọjọ́ Àìkú, 24 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:27:13
Awọn ọmọde naa bi kootu ṣe darukọ wọn ni Bright Edim, ọmọ ọdun mẹẹẹdogun ati Mary Ekong toun naa jẹ ọmọ ọdun mẹẹẹdogun (15) bakan naa.

Ọjọ́ Àìkú, 24 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:11:50
Bo tilẹ jẹ pe ijọba tun fi awọn oṣiṣẹ lọkan balẹ pe lilo AI ko tumọ si pe yoo rọpo awọn eeyan patapata, sibẹ, o ṣee ṣe kawọn kan padanu iṣẹ wọn.

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:58:10
Ileya jẹ́ ọdún tó ṣe pàtàkì sáwọn Mùsùlùmí nítorí òhun ni wọ́n kà kún ọdún ńlá níbi tí wọ́n ti máa ń pa ẹran àgbò.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 16:58:17
O ti to oṣu meloo kan bayii ti faakaja ti n waye laarin Aarẹ Faye ati Olootu ijọba Sonko.

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:30:32
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, DSP Ayanlade Ọlayinka, lo fìdí ọrọ yìí múlẹ nínú atẹjade kan ti o fi sita.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:54:06
Ninu fidio naa ni wọn ti ṣafihan ikọlu kan , ti wọn si n sọ pe awon agbebọn ti wọ Atan Ota, ipinlẹ Ogun.

Ọjọ́ Ajé, 25 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:45:52
Ni bayii, Igboho ti n pe fun awọn ọmọ Yoruba tootọ to ba ṣetan lati darapọ mọ ikọ naa pe ki wọn maa bọ wa.