
Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 15:13:07
Ṣáájú ni ilé ẹjọ́ gíga tó fi ibùjókòó sí ilú Akure, lọ́jọ́ Kẹrìnlélógún oṣù Kọkànlá, ọdún 2025 ti kọ́kọ́ dájọ́ pé Aiyedatiwa kò lè dupò gómìnà ìpínlẹ̀ náà ṣùgbọ́n tí gómìnà pe ìdájọ́ náà ní ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:01:02
Bakan naa ni Motjaba yoo tun koju ipenija iwalaaye orilẹede Iran ati titukọ orilẹede naa atawọn eeyan rẹ jade kuro ninu wahala ati ọgbun eto oselu ati eto ọrọ aje.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:45:14
Atẹjade kan ti agbẹnusọ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Abayomi Jimoh fi lede ni ilu Akure ti n ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo sọ pe Ọjọ Kẹjọ, oṣu Kẹta ọdun 2026 ni awọn ẹṣọ aabo ṣe iṣẹ naa lati daabo bo dukia ati ẹmi awọn ara ilu.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:21:19
BBC News Yoruba kan si igun mejeeji to wa lẹgbẹ oṣelu PDP ipinlẹ Oyo lati fidi ohun to ṣẹlẹ Abamẹta mulẹ

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:26:46
Ilé ẹjọ́ náà ní ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tí PDP pè kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ àti pé ìdájọ́ tí ilé ẹjọ́ gíga kọ́kọ́ gbé kalẹ̀ lọ́jọ́ Kọkànlélọ́gbọ̀n, oṣù Kẹwàá jẹ́ ohun tó tọ̀nà.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:43:00
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:08:58
Iṣẹlẹ naa sẹlẹ lọjọ Aiku ni nnkan bi ago mẹfa irọlẹ.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:29:10
Lọdun yii, oṣu Ramadan ati oṣu awẹ Kristẹni papọ si asiko kan naa fun igba akọkọ lati ọdun 1993.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 11:55:51
Gẹgẹ bi atẹjade ti ajọ NIDCOM fi sita ṣe ṣalaye, ninu ọja ni wọn ti mawọn ọmọ Naijiria mejilelogoji naa ni Mozambique lai sọ nnkan ti wọn ṣe ti wọn fi dero atimọle.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:39:12
Igboho rọ awọn aṣoju ijọba naa ninu atẹjade kan to fi sita wi pe ki wọn lo iriri wọn gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ lati ṣoju Naijiria ni orilẹede ti ijọba n gbe wọn lọ.

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 15:11:56
DCP Placid, psc (+), mni, jẹ ogbotangiri ọmọ ogun ileeṣẹ ọlọpaa to ni ọpọlọpọ iriri, to si tun kawe gboye ni ẹka eto aabo lorilẹede Naijiria ati loke okun.

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 17:23:30
Pẹlu ẹrin ni Power fi ṣalaye eyi lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ lori irinajo igbesi aye ati awọn ohun to lakọja ko to de ibi to wa lonii.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:52:58
Shina Peller ni Baba Okoya lo ṣiṣẹ lati ko dukia rẹ jọ funra rẹ, nitori naa, oun ko lẹtọọ lati sọ fun un bi yoo ṣe pin ogun rẹ.

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:49:35
Nigba to n sọrọ nibi eto kan pẹlu awọn alatilẹyin rẹ, Igboho ni Tinubu lo tu oun silẹ ninu iwe awọn ọdaran, pẹlu atilẹyin awọn ori ade kan nilẹ Yoruba.

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 11:16:28
Ọlọpaa ni ọgbọn eeyan lawọn ti doola bayii amọ omi gbe awọn mii lọ, nigba ti ina mọnamọna gbe awọn ẹlomiran.

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:44:39
Ohun ti a gbọ ni pe bi wọn ṣe n gbe awọn nnkan ninu oko nibi ti wọn ti n sa koro kasu, bẹẹ ni ni wọn gbe awọn mii nibi ti wọn ti n la igi.

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 06:53:20
BBC Yoruba ṣe aridaju wi pe ikọlu yii ṣẹlẹ nigba ti awọn igun kan ninu ẹgbẹ oṣelu naa fẹ yan awọn adari tuntun.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 17:05:11
BBC kan si Sheikh Aminu Ibrahim Aminu Daurawa lati sọrọ nipa nnkan to le ja awẹ.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:42:16
Obasanjo- Bello sọ eyi lasiko to n kopa ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu ileeṣẹ momaworan Channels TV.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:29:55
Orukọ afurasi ọdaran naa ni Gobri Yusuf, iya alagbatọ to si sekupa, yii jẹ ẹgbọn mọmọ rẹ to ti doloogbe saaju

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:07:14
Oluremi ni bo tilẹ jẹ wi pe musulumi ni ọkọ oun toun si jẹ ọmọlẹyin Kristi, o ni kosi ede-aiyede to tii mu kawọn mejeeji pariwo mọ ara awọn lori ri ninu igbeyawo ogoji ọdun awọn.

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:28:53
Awọn imaamu agba naa wa tun woye pe ohun to n ṣẹlẹ lagbaye lọwọ yii ko ṣai kan Naijiria, nitori naa adura fun ijọba lẹka gbogbo, wiwa ọna abayọ si awọn ipenija gbogbo lo yẹ ko mumu lọkan gbogbo mutumuwa.

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:22:46
Orilẹede UAE ṣalaye pe eeyan kan padanu ẹmi rẹ nigba ti awọn ologun naa gbiyanju lati da ado oloro ti Iran yin pada.

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:46:25
Nnkan bii eeyan mọkanlelogoji ni wọn padanu ẹmi wọn ninu ikọlu naa to waye lọjọ karun un, oṣu Kẹfa, ọdun 2022, lasiko ti eeyan bii 140 ti n jọsin.

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:58:27
Obasanjọ lo sọ ọrọ naa nibi eto kan ti wọn ṣe fun niluu Abeokuta lati ṣe ọjọ ibi ọdun mọkandinlaadọrun rẹ loke eepẹ.

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:33:40
Igun Gafcon ninu ijọ Anglican ko ara wọn jọ nílùú Abuja lati Ọjọru ọsẹ yii pẹlu èròngbà láti yan adarí ijọ Anglican ti wọn.

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:20:56
Adajọ James Omotosho lo gbe idajọ kalẹ lori ẹsun mẹtalelogun ti ajọ to n gbe ogun ti ogun oloro lorilẹede, NDLEA fi kan Abba Kyari.

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:33:24
Ninu atẹjade ti wọn fi sita ti Alaga Comr. Oladayo Olabampe, ati Igbakeji, Dọkita Uthman Adedeji si bu ọwọ lu, agbarijọpọ awọn oṣiṣẹ yii salaye awọn kudiẹkudiẹ to n ba ile - iwosan Ijọba apapọ naa finra.

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:24:33
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ ọhun, Olayinka Ayanlade lo fidi iroyin naa mulẹ fun awọn akọroyin niluu Ibadan.

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:49:01
Eto idibo sipo gomina ipinlẹ Ọṣun yoo waye lọjọ karundinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2026 lati mọ boya gomina ipinlẹ Ọṣun Ademọla Adeleke yoo tẹsiwaju fun saa ọdun mẹrin miran tabi boya ẹlomiran ni yoo gba ijoko ile ijọba Abeere lọwọ rẹ.

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 11:03:38
Awọn egungun kaakiri agbaye ni wọn ba wọn peju lati ṣọdun Ẹgungun naa ni orilẹede Benin.

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:25:49
Ninu oṣu kejila ni ileeṣẹ aarẹ fi orukọ awọn aṣoju yii ransẹ si ile igbimọ aṣofin fun ayẹwo ati ibuwọlu.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:48:26
Ọjọ kinni ti Amẹrika ati Israel bẹrẹ ikọli si Iran ni wọn gbẹmi Ayatollah Khamenei.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 05:31:57
Ileeṣẹ alaabo orilẹede Israel tun sọ pe awọn ti kọlu ọkan lara awọn agba ọjẹ ẹgbẹ Hezbollah ni ilu Beirut.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:18:05
Sanyeri lasiko to n sọrọ lori eto “Behind The Fame” sọ pe lasiko ti oun wa ni kekere, oun ko mọ pe fun anfani ara oun ni iwe kika jẹ, oun gbagbọ lasiko naa pe fun anfani awọn obi oun ni.

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 06:37:54
Ọkọ obinrin naa, Matthew Adeleye ati ọmọ rẹ, Tunrayo Adeleye farapa ninu iṣẹlẹ naa, ti wọn si n gba itọju lọwọ.