world-service-rss

BBC News Yorùbá

Ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn dájọ́ lórí ẹ̀tọ́ Aiyedatiwa láti dupò gómìnà Ondo fún sáà míì

Ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn dájọ́ lórí ẹ̀tọ́ Aiyedatiwa láti dupò gómìnà Ondo fún sáà míì

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 15:13:07

Ṣáájú ni ilé ẹjọ́ gíga tó fi ibùjókòó sí ilú Akure, lọ́jọ́ Kẹrìnlélógún oṣù Kọkànlá, ọdún 2025 ti kọ́kọ́ dájọ́ pé Aiyedatiwa kò lè dupò gómìnà ìpínlẹ̀ náà ṣùgbọ́n tí gómìnà pe ìdájọ́ náà ní ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn.

Israel ní Motjaba ọmọ Ali Khameni tó di olórí tuntun fún Iran, ‘ti di ẹni tí àwọn ń fi ikú wá kiri’

Israel ní Motjaba ọmọ Ali Khameni tó di olórí tuntun fún Iran, 'ti di ẹni tí àwọn ń fi ikú wá kiri'

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:01:02

Bakan naa ni Motjaba yoo tun koju ipenija iwalaaye orilẹede Iran ati titukọ orilẹede naa atawọn eeyan rẹ jade kuro ninu wahala ati ọgbun eto oselu ati eto ọrọ aje.

Ọwọ́ tẹ àwọn afurasí ọ̀daràn 99 ní ìpínlẹ̀ Ondo

Ọwọ́ tẹ àwọn afurasí ọ̀daràn 99 ní ìpínlẹ̀ Ondo

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:45:14

Atẹjade kan ti agbẹnusọ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Abayomi Jimoh fi lede ni ilu Akure ti n ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo sọ pe Ọjọ Kẹjọ, oṣu Kẹta ọdun 2026 ni awọn ẹṣọ aabo ṣe iṣẹ naa lati daabo bo dukia ati ẹmi awọn ara ilu.

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìjà ńlá tó bẹ́ sílẹ̀ láàárín àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Oyo

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìjà ńlá tó bẹ́ sílẹ̀ láàárín àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Oyo

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:21:19

BBC News Yoruba kan si igun mejeeji to wa lẹgbẹ oṣelu PDP ipinlẹ Oyo lati fidi ohun to ṣẹlẹ Abamẹta mulẹ

Ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn gbé ìdájọ́ kalẹ̀ lórí àpérò ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó wáyé ní Ibadan

Ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn gbé ìdájọ́ kalẹ̀ lórí àpérò ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó wáyé ní Ibadan

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:26:46

Ilé ẹjọ́ náà ní ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tí PDP pè kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ àti pé ìdájọ́ tí ilé ẹjọ́ gíga kọ́kọ́ gbé kalẹ̀ lọ́jọ́ Kọkànlélọ́gbọ̀n, oṣù Kẹwàá jẹ́ ohun tó tọ̀nà.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:43:00

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Àwọn agbébọn jí Ìmáàmù àti àwọn mẹ́rin míì gbé ní Kwara.

Àwọn agbébọn jí Ìmáàmù àti àwọn mẹ́rin míì gbé ní Kwara.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:08:58

Iṣẹlẹ naa sẹlẹ lọjọ Aiku ni nnkan bi ago mẹfa irọlẹ.

Wo tọkọtaya tó ń gba àwẹ̀ Lent àti Ramadan papọ̀

Wo tọkọtaya tó ń gba àwẹ̀ Lent àti Ramadan papọ̀

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:29:10

Lọdun yii, oṣu Ramadan ati oṣu awẹ Kristẹni papọ si asiko kan naa fun igba akọkọ lati ọdun 1993.

Ẹ tú ọmọ Naijiria 42 tí ẹ jù sátìmọ́lé sílẹ̀ ní Mozambique, Dabiri-Erewa ké gbàjarè

Ẹ tú ọmọ Naijiria 42 tí ẹ jù sátìmọ́lé sílẹ̀ ní Mozambique, Dabiri-Erewa ké gbàjarè

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 11:55:51

Gẹgẹ bi atẹjade ti ajọ NIDCOM fi sita ṣe ṣalaye, ninu ọja ni wọn ti mawọn ọmọ Naijiria mejilelogoji naa ni Mozambique lai sọ nnkan ti wọn ṣe ti wọn fi dero atimọle.

Sunday Igboho gba àwọn aṣojú ìjọba Nàìjíríà tuntun sílẹ̀ òkèèrè lámọ̀ràn, Ó ní ‘ẹ bá Tinubu ṣíṣẹ́ pọ̀ láti yí orúkọ Naijiria padà sí rere’

Sunday Igboho gba àwọn aṣojú ìjọba Nàìjíríà tuntun sílẹ̀ òkèèrè lámọ̀ràn, Ó ní 'ẹ bá Tinubu ṣíṣẹ́ pọ̀ láti yí orúkọ Naijiria padà sí rere'

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:39:12

Igboho rọ awọn aṣoju ijọba naa ninu atẹjade kan to fi sita wi pe ki wọn lo iriri wọn gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ lati ṣoju Naijiria ni orilẹede ti ijọba n gbe wọn lọ.

Mọ̀ nípa Anthony Okon Placid tó rọ́pò Benjamin Hundeyin gẹ́gẹ́ bíi Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Naijiria

Mọ̀ nípa Anthony Okon Placid tó rọ́pò Benjamin Hundeyin gẹ́gẹ́ bíi Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Naijiria

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 15:11:56

DCP Placid, psc (+), mni, jẹ ogbotangiri ọmọ ogun ileeṣẹ ọlọpaa to ni ọpọlọpọ iriri, to si tun kawe gboye ni ẹka eto aabo lorilẹede Naijiria ati loke okun.

Wọ́n sanwó fún mi láti jẹ́ kí Portable lù mí ní - Kelvin Power

Wọ́n sanwó fún mi láti jẹ́ kí Portable lù mí ní - Kelvin Power

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 17:23:30

Pẹlu ẹrin ni Power fi ṣalaye eyi lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ lori irinajo igbesi aye ati awọn ohun to lakọja ko to de ibi to wa lonii.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Mi ò sọ pé àwọn ọmọ Bàbá Rasaq Okoya kékeré ni yóò jogún rẹ̀, ohun tí mo sọ rèé - Shina Peller

Mi ò sọ pé àwọn ọmọ Bàbá Rasaq Okoya kékeré ni yóò jogún rẹ̀, ohun tí mo sọ rèé - Shina Peller

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:52:58

Shina Peller ni Baba Okoya lo ṣiṣẹ lati ko dukia rẹ jọ funra rẹ, nitori naa, oun ko lẹtọọ lati sọ fun un bi yoo ṣe pin ogun rẹ.

Mo máa fi gbogbo ayé mi tẹ̀lé Tinubu ni, òun ló yọ okùn tí Buhari fi sí mi lọ́rùn kúrò - Sunday Igboho

Mo máa fi gbogbo ayé mi tẹ̀lé Tinubu ni, òun ló yọ okùn tí Buhari fi sí mi lọ́rùn kúrò - Sunday Igboho

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:49:35

Nigba to n sọrọ nibi eto kan pẹlu awọn alatilẹyin rẹ, Igboho ni Tinubu lo tu oun silẹ ninu iwe awọn ọdaran, pẹlu atilẹyin awọn ori ade kan nilẹ Yoruba.

Omi gbé èèyàn 23 lọ ní Kenya lẹ́yìn òjò àrọ̀rọ̀dá

Omi gbé èèyàn 23 lọ ní Kenya lẹ́yìn òjò àrọ̀rọ̀dá

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 11:16:28

Ọlọpaa ni ọgbọn eeyan lawọn ti doola bayii amọ omi gbe awọn mii lọ, nigba ti ina mọnamọna gbe awọn ẹlomiran.

Àwọn ajínigbé jí àwọn tó ń ṣa kóró kaṣú àtàwọn tó ń la igi lóko gbé lọ ní Kwara, wọ́n ń béèrè fún N10m

Àwọn ajínigbé jí àwọn tó ń ṣa kóró kaṣú àtàwọn tó ń la igi lóko gbé lọ ní Kwara, wọ́n ń béèrè fún N10m

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:44:39

Ohun ti a gbọ ni pe bi wọn ṣe n gbe awọn nnkan ninu oko nibi ti wọn ti n sa koro kasu, bẹẹ ni ni wọn gbe awọn mii nibi ti wọn ti n la igi.

Kí ló máwọn afurasí jàndùkú olóṣèlú ya wọ ilé Igbákejì Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo tẹ́lẹ̀ n’Ibadan, ba ọ̀pọ̀ dúkìá jẹ́? Àlàyé rèé

Kí ló máwọn afurasí jàndùkú olóṣèlú ya wọ ilé Igbákejì Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo tẹ́lẹ̀ n'Ibadan, ba ọ̀pọ̀ dúkìá jẹ́? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Àìkú, 8 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 06:53:20

BBC Yoruba ṣe aridaju wi pe ikọlu yii ṣẹlẹ nigba ti awọn igun kan ninu ẹgbẹ oṣelu naa fẹ yan awọn adari tuntun.

Wo nǹkan mẹ́wàá yàtọ̀ sí oúnjẹ àti omi tó tó lè já ààwẹ̀ rẹ lásìkò Ramadan

Wo nǹkan mẹ́wàá yàtọ̀ sí oúnjẹ àti omi tó tó lè já ààwẹ̀ rẹ lásìkò Ramadan

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 17:05:11

BBC kan si Sheikh Aminu Ibrahim Aminu Daurawa lati sọrọ nipa nnkan to le ja awẹ.

2027: Bàbá mi yóò dìbò fún mi, olùdíje tó kájú ẹ̀ ni mí-Iyabo Obasanjo

2027: Bàbá mi yóò dìbò fún mi, olùdíje tó kájú ẹ̀ ni mí-Iyabo Obasanjo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:42:16

Obasanjo- Bello sọ eyi lasiko to n kopa ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu ileeṣẹ momaworan Channels TV.

Ọwọ́ ọlọ́pàá Kwara tẹ afurasí ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gún (15) kan tó ṣekú pa alágbàtọ́ rẹ̀ ní Kwara

Ọwọ́ ọlọ́pàá Kwara tẹ afurasí ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gún (15) kan tó ṣekú pa alágbàtọ́ rẹ̀ ní Kwara

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:29:55

Orukọ afurasi ọdaran naa ni Gobri Yusuf, iya alagbatọ to si sekupa, yii jẹ ẹgbọn mọmọ rẹ to ti doloogbe saaju

Ìdí tí èmi àti Tinubu kò fi gbéná wojú ara wa rí láti ìgbà tí a ti ṣègbéyàwó fún bíi ogójì ọdún - Oluremi Tinubu

Ìdí tí èmi àti Tinubu kò fi gbéná wojú ara wa rí láti ìgbà tí a ti ṣègbéyàwó fún bíi ogójì ọdún - Oluremi Tinubu

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 7 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:07:14

Oluremi ni bo tilẹ jẹ wi pe musulumi ni ọkọ oun toun si jẹ ọmọlẹyin Kristi, o ni kosi ede-aiyede to tii mu kawọn mejeeji pariwo mọ ara awọn lori ri ninu igbeyawo ogoji ọdun awọn.

Fìtínà ni ogun tó ń wáyé láàárín Amẹ́ríkà-Israel àti Iran, ẹ yé dá sí ohun tí kò kàn yín nípa rẹ̀ – Ìgbìmọ̀ àwọn Imáàmù kìlọ̀

Fìtínà ni ogun tó ń wáyé láàárín Amẹ́ríkà-Israel àti Iran, ẹ yé dá sí ohun tí kò kàn yín nípa rẹ̀ – Ìgbìmọ̀ àwọn Imáàmù kìlọ̀

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:28:53

Awọn imaamu agba naa wa tun woye pe ohun to n ṣẹlẹ lagbaye lọwọ yii ko ṣai kan Naijiria, nitori naa adura fun ijọba lẹka gbogbo, wiwa ọna abayọ si awọn ipenija gbogbo lo yẹ ko mumu lọkan gbogbo mutumuwa.

Kí ló dé tí Iran fi ń ju àdó olóró sáwọn orílẹ́èdè mùsùlùmí tó wà ní àyíká rẹ̀? Ohun ti a mọ̀ rèé

Kí ló dé tí Iran fi ń ju àdó olóró sáwọn orílẹ́èdè mùsùlùmí tó wà ní àyíká rẹ̀? Ohun ti a mọ̀ rèé

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:22:46

Orilẹede UAE ṣalaye pe eeyan kan padanu ẹmi rẹ nigba ti awọn ologun naa gbiyanju lati da ado oloro ti Iran yin pada.

Afurasí tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì ìlú Owo ṣàlàyé bí ọwọ́ DSS ṣe tẹ̀ ẹ́

Afurasí tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì ìlú Owo ṣàlàyé bí ọwọ́ DSS ṣe tẹ̀ ẹ́

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:46:25

Nnkan bii eeyan mọkanlelogoji ni wọn padanu ẹmi wọn ninu ikọlu naa to waye lọjọ karun un, oṣu Kẹfa, ọdun 2022, lasiko ti eeyan bii 140 ti n jọsin.

Ikú kẹ̀, mo kú tì, lákọ ni mo wà bí ìbọn – Ààrẹ tẹ́lẹ̀ Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ lórí àwọn tó ń gbé ìròyìn ikú rẹ̀ kiri

Ikú kẹ̀, mo kú tì, lákọ ni mo wà bí ìbọn – Ààrẹ tẹ́lẹ̀ Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ lórí àwọn tó ń gbé ìròyìn ikú rẹ̀ kiri

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:58:27

Obasanjọ lo sọ ọrọ naa nibi eto kan ti wọn ṣe fun niluu Abeokuta lati ṣe ọjọ ibi ọdun mọkandinlaadọrun rẹ loke eepẹ.

Nǹkan yan nínú ìjọ Anglican, àwọn àlùfáà tó pe ara wọn ní Gafcon lábẹ́ ìjọ náà yan bísọ́ọ̀bù àgbà tuntun tako bíṣọ́ọ̀bù Canterbury

Nǹkan yan nínú ìjọ Anglican, àwọn àlùfáà tó pe ara wọn ní Gafcon lábẹ́ ìjọ náà yan bísọ́ọ̀bù àgbà tuntun tako bíṣọ́ọ̀bù Canterbury

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:33:40

Igun Gafcon ninu ijọ Anglican ko ara wọn jọ nílùú Abuja lati Ọjọru ọsẹ yii pẹlu èròngbà láti yan adarí ijọ Anglican ti wọn.

Ilé ẹjọ́ yọ̀ǹda Abba Kyari, wọ́n ní kò lẹ́jọ́ ọ́ jẹ́ lórí àwọn dúkìá tí kò kéde

Ilé ẹjọ́ yọ̀ǹda Abba Kyari, wọ́n ní kò lẹ́jọ́ ọ́ jẹ́ lórí àwọn dúkìá tí kò kéde

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:20:56

Adajọ James Omotosho lo gbe idajọ kalẹ lori ẹsun mẹtalelogun ti ajọ to n gbe ogun ti ogun oloro lorilẹede, NDLEA fi kan Abba Kyari.

Àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn UCH gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ Márùn-ún, dá aláìsàn padà

Àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn UCH gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ Márùn-ún, dá aláìsàn padà

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:33:24

Ninu atẹjade ti wọn fi sita ti Alaga Comr. Oladayo Olabampe, ati Igbakeji, Dọkita Uthman Adedeji si bu ọwọ lu, agbarijọpọ awọn oṣiṣẹ yii salaye awọn kudiẹkudiẹ to n ba ile - iwosan Ijọba apapọ naa finra.

Ajínigbé kọlu ìpínlẹ̀ Oyo, jí èèyàn mẹ́rin gbé lójú ọ̀nà Igbeti sí Kishi

Ajínigbé kọlu ìpínlẹ̀ Oyo, jí èèyàn mẹ́rin gbé lójú ọ̀nà Igbeti sí Kishi

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:24:33

Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ ọhun, Olayinka Ayanlade lo fidi iroyin naa mulẹ fun awọn akọroyin niluu Ibadan.

INEC gbé orúkọ àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú tí yóò díje ìbò gómìnà Osun jáde, PDP àti Labour kò sí níbẹ̀

INEC gbé orúkọ àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú tí yóò díje ìbò gómìnà Osun jáde, PDP àti Labour kò sí níbẹ̀

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:49:01

Eto idibo sipo gomina ipinlẹ Ọṣun yoo waye lọjọ karundinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2026 lati mọ boya gomina ipinlẹ Ọṣun Ademọla Adeleke yoo tẹsiwaju fun saa ọdun mẹrin miran tabi boya ẹlomiran ni yoo gba ijoko ile ijọba Abeere lọwọ rẹ.

Wo bí àwọn Egúngún ṣe dá àrà sílẹ̀ ní orílẹ̀èdè Benin

Wo bí àwọn Egúngún ṣe dá àrà sílẹ̀ ní orílẹ̀èdè Benin

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 11:03:38

Awọn egungun kaakiri agbaye ni wọn ba wọn peju lati ṣọdun Ẹgungun naa ni orilẹede Benin.

Wo àwọn aṣojú 65 tí Ààrẹ Tinubu fi ránṣẹ́ sílẹ̀ òkèèrè àti ìlú tí wọ́n ti ń ṣojú wa

Wo àwọn aṣojú 65 tí Ààrẹ Tinubu fi ránṣẹ́ sílẹ̀ òkèèrè àti ìlú tí wọ́n ti ń ṣojú wa

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:25:49

Ninu oṣu kejila ni ileeṣẹ aarẹ fi orukọ awọn aṣoju yii ransẹ si ile igbimọ aṣofin fun ayẹwo ati ibuwọlu.

Ìkọlù Amẹ́ríkà àti Israel sí Iran ti gbẹ̀mì Ayatollah Khamenei lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún lórí oyè; kí ni ipa rẹ̀ nínú ohun tó fa ogun náà?

Ìkọlù Amẹ́ríkà àti Israel sí Iran ti gbẹ̀mì  Ayatollah Khamenei lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún lórí oyè; kí ni ipa rẹ̀ nínú ohun tó fa ogun náà?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:48:26

Ọjọ kinni ti Amẹrika ati Israel bẹrẹ ikọli si Iran ni wọn gbẹmi Ayatollah Khamenei.

Àwa kọ́ la bẹ̀rẹ̀ ogun pẹ̀lú Iran, ṣùgbọ́n àwa la máà fòpin síi – Hegseth, alákóso ètò àbò nílẹ̀ Amẹ́ríkà

Àwa kọ́ la bẹ̀rẹ̀ ogun pẹ̀lú Iran, ṣùgbọ́n àwa la máà fòpin síi – Hegseth, alákóso ètò àbò nílẹ̀ Amẹ́ríkà

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 05:31:57

Ileeṣẹ alaabo orilẹede Israel tun sọ pe awọn ti kọlu ọkan lara awọn agba ọjẹ ẹgbẹ Hezbollah ni ilu Beirut.

Ìfìyàjẹni látọ̀dọ̀ àwọn òbí mi ni mo ka ètò ẹ̀kọ́ sí nígbà èwe mi, àmọ́ nísisìyí, mo ń k’àbámọ̀ pé mi ò kàwé – Sanyeri

Ìfìyàjẹni látọ̀dọ̀ àwọn òbí mi ni mo ka ètò ẹ̀kọ́ sí nígbà èwe mi, àmọ́ nísisìyí, mo ń k'àbámọ̀ pé mi ò kàwé – Sanyeri

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:18:05

Sanyeri lasiko to n sọrọ lori eto “Behind The Fame” sọ pe lasiko ti oun wa ni kekere, oun ko mọ pe fun anfani ara oun ni iwe kika jẹ, oun gbagbọ lasiko naa pe fun anfani awọn obi oun ni.

Ọmọ bàbá onílé gún ayálégbé pa lórí èdè àyedè owó ilé

Ọmọ bàbá onílé gún ayálégbé pa lórí èdè àyedè owó ilé

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 06:37:54

Ọkọ obinrin naa, Matthew Adeleye ati ọmọ rẹ, Tunrayo Adeleye farapa ninu iṣẹlẹ naa, ti wọn si n gba itọju lọwọ.