
Ọjọ́ Àìkú, 12 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 07:54:38
Lọwọlọwọ yii, apejọpọ marun-un lo jẹ koko ti wọn si gbajumọ ju lagbaaye, eyi to jẹ ti ẹsin.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 18:59:32
Ọrọ yii lo wa ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ijọba Amẹrika to n ri si ọrọ abẹnu fi lede lori itakun ayelujare wọn.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 19:02:12
Agbẹnusọ sọ fun ajọ FRSC ẹka ti ipinlẹ Ogun, Ọgbẹni Afolabi Odunsi, lo fidi ọrọ yii mulẹ fun ileeṣẹ iroyin NAN.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:11:46
Ọba Olaoye lanfaani lati ri awọn akẹẹkọ at’awọn olukọ naa lasiko ti o kan sí ẹka ileeṣẹ ọmogun Naijiria to wa niluu Ibadan nibi ti kabiyesi ti gboṣuba kare fun ọga agba oludari ẹka naa to wa ni agbegbe Ojoo fun iṣẹ takun takun ti wọn ṣe lori bi wọn ṣe doola awọn akẹẹkọ at’awọn olukọ naa.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:01:57
Bo tilẹ jẹ pe o ni ijọba ko ti pe oun lati sọ fun oun pe iyawo oun ti wa lakata wọn titi di asiko ti a n ba oun sọrọ amọ inu oun dun.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:11:20
Ninu ifọrọwerọ kan ti agba oṣere naa ṣe pẹlu AfricanAList lo ti ṣalaye irinajo rẹ ninu sinima ṣiṣe ati igbeaye rẹ lai si ninu sinima.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:32:30
Ẹgbẹrun lọna ọgọrun kan naira ni ijọba gbe owo oṣu naa si bayii, lati ẹgbẹrun mọkandinlaadọta naira ti wọn n gba tẹlẹ gẹgẹ bi owo oṣu.

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:38:33
Ounjẹ alẹ ti Habeeb fẹ jẹ la gbọ pe o lọ ra to fi lugbadi iku ojiji ninu ija Yoruba ati Hausa naa

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:50:50
Chatta ninu fidio kan to fi sori ikanni Instagram rẹ, sọ pe oun sọrọ sita lori iṣẹlẹ naa lẹyin ti awọn eeyan n fi oun ṣe yẹyẹ lori ọrọ naa lori ayelujara.

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 14:22:50
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:34:20
Ẹsun mejila ọtọọtọ to nii ṣe pẹlu iwa ajẹbanu ni ajọ naa fi kan Miyetti Allah niwaju ile-ẹjọ, eyi ti wọn sọ pe wọn tẹwọ gba obitibiti owo ilẹ okeere ọhun, ti wọn lo lodi si ofin.

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:12:59
Amẹrika ni awọn ṣe ikọlu si ibudo awọn oloogun Iran to jẹ aadọrun-un. Iran sọ pe eeyan mẹrinla ni Amẹrika ti pa lẹnu ikọlu ọjọ meji naa.

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:14:52
Ipinlẹ Sokoto ni Ọgagun Musa ti sọrọ yii, lasiko ti wọn n pin awọn ọkọ akọtami fawọn ẹka alaabo .

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:23:22
Ọjọ kejila, oṣu Kẹfa ọdun 2026 yii ni Olatunji Emmanuel Okedeyi gbera kuro niluu London.

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:15:56
Kitan Oyesiku ati ẹṣọ alaabo rẹ, Pelumi Adetayo ni awọn amookunṣeka naa pa nipakupa laipẹ yii niluu Kobape to wa loju ọna marosẹ Abeokuta si Sagamu.

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:38:49
Ọlọpaa ni awọn ri ibọn ilewọ agbelẹrọ meji, ọta ibọn, awọn iboju meji, ẹrọ ilewọ ati kaadi ATM lakata wọn lẹyin ikọlu naa.

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:53:38
Gomina tẹlẹri nipinlẹ Anambra sọ pe ọpọ awọn ẹtọ oun ni ijọba ilẹ Naijiria fi n dunkooko mọ oun, ati pe gbogbo awọn to duro gẹgẹ bi alatako ijọba ni wọn n dojukọ idunkooko loriṣiriṣi.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 09:58:35
Adele Alukoro fun ẹka ologun apapọ lapa Ariwa-Ila-Oorun Naijiria, Ọgagun Muhammed Goni, fidi ikọlu naa mulẹ ninu atẹjade to fi sita l’Ọjọbọ, ọjọ kẹsan-an oṣu Keje ọdun 2026 yii.

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 15:17:30
CBN sọ pe ki gbogbo awọn to n kọ lati maa gba owo ọgọrun kan naira naa dẹkun iwa naa bayii, nitori pe owo ọhun ṣi n jẹ itẹwọgba labẹ aṣẹ, akoso ati ofin ilẹ Naijiria.

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 05:46:10
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara ṣafihan bi Adeyemi ṣe n ba gbajumọ ori ayelujara, Martins Otse ti ọpọ eeyan mọ si VeryDarkMan sọrọ.

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:33:08
Ẹgbẹ naa ti orukọ wọn n jẹ Traditional Religion Worshippers Association of Osun State (TRAWSO), ṣekilọ yii lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Oṣogbo lọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii.

Ọjọ́rú, 8 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:55:19
Ẹ o ranti pe El-Rufai ti wa ni gbaga ijọba lati oṣu keji ọdun 2026 lori ẹsun ajẹbanu atawọn mi-in tijọba apapọ n ba a fa.

Ọjọ́rú, 8 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:40:36
Gẹgẹ bi awọn ẹka ẹṣọ aabo ṣe n fidi ẹ mulẹ, wọn ni ẹkọ ti n fi oju mimu han lẹyin ti wọn ti mọ awọn to wa nidii ijinigbe naa, atawọn alajọṣiṣẹ pọ wọn.

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 09:16:09
Adari ajọ NiHSA Umar Mohammed, ni awọn ti kilọ fun awọn ọmọ Naijiria ṣaaju iṣẹlẹ ọhun amọ gbogbo ikilọ awọn ni araalu kọ eti ọgbọin si.

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:04:45
James ninu fidio kan ti Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Delta, Bright Edafe fi sita lọjọ Aiku, ṣalaye pe oun mọ-ọn-mọ wọgbo lọ, oun si pe iya oun lori aago pe wọn ti ji oun gbe.

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:45:57
Ọlọpaa sọ pe ikọlu ti eegun naa atawọn ọmọ ẹyin rẹ si si ọkunrin naa lo pa a lọjọ Aiku, ọjọ karun-un oṣu Keje ọdun 2026.

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:40:05
Aṣoju ajọ IMF ni Naijiria, Christian Ebeke, sọ niluu Eko pe nnkan bii ida meji owo ti ijọba Naijiria na ni ko si akọsilẹ rẹ rara, bo tilẹ jẹ pe o yẹ ki akọsilẹ rẹ wa.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 05:56:32
Ninu ibanujẹ ọkan ni ẹbi Adewale, ẹṣọ Sam Larry to ku ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lopopona marosẹ Eko si Calabar wa bayii.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 07:56:58
Davido sọ fun BBC News Africa wi pe ko ṣee ṣe ki oun kọ eti ikun si eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria papaa julọ ijinigbe awọn akẹkọọ mọkandinlogoji atawọn olukọ meje to ṣẹlẹ ni ijọba ibilẹ Oriire nipinlẹ Oyo.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:21:29
Portable sọrọ yii ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti o ṣe pẹlu awọn akọroyin ori itakun ayelujara.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:51:43
Nnani la gbọ pe o ki aye pe o digboṣe lẹyin to fara kaaṣa ado oloro ti awọn ọmọ ogun orileede Russia ju si ilẹ Ukraine lasiko ikọlu.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:18:15
Atẹjade ti ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ati Osun fisita lori ayajọ ẹgbẹ okunkun 7-7, ti wa n sin awọn araalu ni gbẹrẹ ipakọ pe ki wọn fura nipa ọsẹ tawọn ẹlẹgbẹ okunkun naa le se.okunkun naa le se.

Ọjọ́rú, 8 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:09:40
Iyabo Ojo ṣalaye pe ipinya oun ati ọkọ toun bimọ fun ko kan awọn tawọn bi.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 4 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 14:46:55
Gẹgẹ bi wọn ṣe kede, o kere tan, isinku naa yoo gba wọn to ọjọ mẹfa.

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:21:05
Ẹ o ranti pe bii ọsẹ mẹta sẹyin ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe afurasi adigunjale ni Surii Ilupeju ati pe ọpọ awọn ohun ija oloro bii ibọn atawọn nnkan mii ni awọn ba ninu ile rẹ nigba ti awọn ṣabẹwo sibẹ.

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:00:11
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ologun Mali fi sita ni wọn ti ṣalaye, pe alaafia ti jọba ni ilu marun-un ti awon agbesunmọmin naa dojukọ.

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:04:07
Ọdun 1990 ni obìnrin mẹẹdogun kan da abule naa silẹ, lẹyin ti wọn bọ lọwọ awọn ọmọ ogun ilẹ Gẹẹsi to n fi ipa ba wọn lo pọ.

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:26:35
Lọjọ kẹẹdọgbọn oṣù Karun un lawọn janduku agbébọn yawọ ile ẹkọ girama to wa ni Esinele ati ile ẹkọ alakọbẹrẹ ni Yawota ní ìjọba ìbílẹ̀ Oriire; nibi ti wọn ti ji àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ to le logoji lọ.

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 17:08:03
Atẹjade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ to n ri si eto irinna silẹ okeere, Imomotimi Ebienfa fi lede lọjọ Karun-un, oṣu Keje sọ pe awọn eeyan to padanu ẹmi wọn naa ni Emeka Charles Ibegbeu ati Nnaemeka Mathew Andrew Ekepynong.

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:04:50
Gẹgẹ bi awọn araalu ti ikọlu naa ṣoju wọn ṣe sọ, ikọlu naa waye nigba ti awọn agbebon meji kan fẹ gbiyanju lati ja ọkada agbẹ kan gba.

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:33:28
Miliọnu mẹwaa aabọ naira ni araalu kọkọ san fun awọn ajinigbe naa, ki wọn to fi mẹwaa miran-an kun un bi wọn ṣe sọ.