world-service-rss

BBC News Yorùbá

Ṣé gbogbo àgbáyé yóò tún dojúkọ làásìgbò epo rọ̀bì tó wáyé lọ́dún 1970 bí?

Ṣé gbogbo àgbáyé yóò tún dojúkọ làásìgbò epo rọ̀bì tó wáyé lọ́dún 1970 bí?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 31 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:00:44

Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé làásìgbò méjéèjì dá lórí epo, àwọn onímọ̀ sọ pé ìyàtọ̀ wà lára nǹkan tó wáyé lọ́dún 1970 àti àsìkò yìí.

Ìjọba Plateau kéde ìṣéde ọlọ́jọ́ méjì lẹ́yìn ìkọlù agbébọn, léri láti máṣe sin àwọn òkú ní àsinpọ̀

Ìjọba Plateau kéde ìṣéde ọlọ́jọ́ méjì lẹ́yìn ìkọlù agbébọn, léri láti máṣe sin àwọn òkú ní àsinpọ̀

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 31 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:05:18

Ikọ̀ ìròyìn BBC lọsí ìlú Gari Ya Waye, lágbègbè Angwan Rukuba, ní ìpínlẹ̀ Plateau níbi tí agbébọn ti gbẹ̀mí èèyàn tó tó ogún, tí ọ̀pọ̀ sì fara pa, àkójọpọ̀ ìròyìn tí a mú bọ̀ rèé.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 31 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:37:35

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Wo ìgbésẹ̀ mẹ́sàn-án tí o máa gbé láti ṣe ìṣirò owó orí tí ò ń san fún ìjọba lọ́dọọdún

Wo ìgbésẹ̀ mẹ́sàn-án tí o máa gbé láti ṣe ìṣirò owó orí tí ò ń san fún ìjọba lọ́dọọdún

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 31 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:45:15

Gẹgẹ bi ofin owo ori tuntun ọdun 2025 sẹ laa kalẹ, gbogbo ọmọ Naijiria to n san owo ori gbọdọ maa ṣe iṣiro owo ori ti wọn san lọdọọdun.

Iléeṣẹ́ aṣojú Nàíjíríà gbé kókó ọ̀rọ̀ mẹ́wàá jáde lórí ìwọ́de tó ń wáyé ní South Africa

Iléeṣẹ́ aṣojú Nàíjíríà gbé kókó ọ̀rọ̀ mẹ́wàá jáde lórí ìwọ́de tó ń wáyé ní South Africa

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 31 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:22:00

Ìfẹ̀hónúhàn yìí ló ń wáyé lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀ tí wọ́n fi ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Solomon Ogbonna Eziko jẹ oyè olórí ẹ̀yà Igbo East London.

Ipa wo ni ìdarapọ̀ Kwankwaso mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú ADC máa ní lórí ìbò 2027?

Ipa wo ni ìdarapọ̀ Kwankwaso mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú ADC máa ní lórí ìbò 2027?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 31 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:31:25

Kwankwaso sọ fún àwọn alátìlẹyìn rẹ̀ náà láti ri dájú pé wọ́n forúkọ sílẹ̀ pẹ̀lú ADC, kí wọ́n sì ri dájú láti gba káàdì ìdìbò ṣáájú ètò ìdìbò ọdún 2027.

INEC ṣe àyípadà orúkọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ PDP sí ti igun Wike dìbò yàn lópin ọ̀sẹ̀

INEC ṣe àyípadà orúkọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ PDP sí ti igun Wike dìbò yàn lópin ọ̀sẹ̀

Ọjọ́ Ajé, 30 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:18:33

Àwọn aṣojú tí iye wọn tó 2,500 tó kópa níbi àpérò náà ló fẹnukò láti gbé àwọn aláṣẹ tuntun náà wọlé láì ṣe ètò ìdìbò kankan gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ náà ti ṣáájú kéde pé ìlànà fífi ẹnu kò lórí àwọn olùdíje ni àwón máa ṣe dípò ṣíṣe ètò ìdìbò.

Kí ló fà á tí Funke Akindele kò fi dáhùn kíkí tí Toyin Abraham kí i lóde?

Kí ló fà á tí Funke Akindele kò fi dáhùn kíkí tí Toyin Abraham kí i lóde?

Ọjọ́ Ajé, 30 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:48:05

Bi fidio ọhun ṣe han to, ti ohun to ṣẹlẹ nibẹ ko ruju rara, aṣiri ohun to fa a ti Funke Akindele fi leju pa ko ti I han sita.

Àjọ̀dún Lisabi 2026 gbọ̀rẹ̀gẹ̀jigẹ̀ lóòótọ́, àmọ́, a ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mẹ́yẹ bọ̀ lápò ni - Amosun

Àjọ̀dún Lisabi 2026 gbọ̀rẹ̀gẹ̀jigẹ̀ lóòótọ́, àmọ́, a ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mẹ́yẹ bọ̀ lápò ni - Amosun

Ọjọ́ Àìkú, 29 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 19:07:34

Liṣabi ni jagunjagun to lewaju awọn Ẹgba kuro niluu Oyo lọdun 1830 lati tẹdo si abẹ Olumo.

Wo ohun tó mú àyájọ́ ọjọ́ ìsinmi ‘Palm Sunday’ yàtọ̀

Wo ohun tó mú àyájọ́ ọjọ́ ìsinmi 'Palm Sunday' yàtọ̀

Ọjọ́ Àìkú, 29 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 14:21:49

Ayajọ yii jẹ ọjọ ti awọn ọmọlẹyin Kristi fi maa n ṣe ami bi Jesu Kristi ṣe gun kẹtẹkẹtẹ wọ Jerusalem nigba to fi wa laye.

Lẹ́yìn ìpàdé àpapọ̀ l’Abuja, wo àwọn tí yóó tukọ̀ APC fọ́dún mẹ́rin

Lẹ́yìn ìpàdé àpapọ̀ l'Abuja, wo àwọn tí yóó tukọ̀ APC fọ́dún mẹ́rin

Ọjọ́ Àìkú, 29 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:21:16

Nibi ipade ọhun ni wọn tun ti yan Alaga apapọ wọn, Nentawe Yilwatda ati Ajibola Basiru pada sipo alaga ati Akọwe apapọ ẹgbẹ APC.

Rògbòdìyàn PDP: Wo àwọn tọ kọ̀yìn sí ìpàdé àpapọ̀ igun Wike tí yóò wáyé l’Abuja lónìí

Rògbòdìyàn PDP: Wo àwọn tọ kọ̀yìn sí ìpàdé àpapọ̀ igun Wike tí yóò wáyé l'Abuja lónìí

Ọjọ́ Àìkú, 29 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:25:31

Pẹlu bi ẹgbẹ PDP ṣe ti pin, ti awọn alaga ẹgbẹ ti ṣe ọtọọtọ, ti ọpọ gomina PDP si ti kuro nibẹ, awọn kan ti sọ pe awọn ko ni i de ibi ipade ti Wike atawọn eeyan rẹ gbe kalẹ yii.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Afẹ́fẹ́ òjò fa ìjàmbá ọkọ̀ ńlá l’Osogbo

Afẹ́fẹ́ òjò fa ìjàmbá ọkọ̀ ńlá l'Osogbo

Ọjọ́ Àìkú, 29 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:03:36

Ni deede aago mẹjọ alẹ ọjọ Àbámẹ́ta naa ni ojo to mu afẹfẹ nla dani naa rọ to si ba ọpọlọpọ nnkan jẹ niluu Osogbo.

Agbébọn 38 pàdé ikú lọ́wọ́ ológun Naijiria, wọ́n gba ìbọn AK-47 àti àdó olóró lọ́wọ́ wọn

Agbébọn 38 pàdé ikú lọ́wọ́ ológun Naijiria, wọ́n gba ìbọn AK-47 àti àdó olóró lọ́wọ́ wọn

Ọjọ́ Àìkú, 29 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 06:06:25

Ikọ ti a tun a mọ si Operation Hadin Kai naa sọ pe owurọ kutu ọjọ Satide, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta ọdun 2026 yii ni awọn mu awọn eeyan naa balẹ.

Agbébọn tó kó òṣìṣẹ́ mẹ́ta lọ nílé ìwòsàn l’Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé

Agbébọn tó kó òṣìṣẹ́ mẹ́ta lọ nílé ìwòsàn l'Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 15:17:51

Awọn agbebọn naa ya wọ ile iwosan ọhun ni deede aago meji oru ọjọ Abamẹta, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta ọdun 2026 yii, wọn si ko awọn osisẹ ibẹ mẹta lọ.

Yilwatda wọlé padà bíi Alága àpapọ̀ APC pẹ̀lú àwọn olóyè ẹgbẹ́

Yilwatda wọlé padà bíi Alága àpapọ̀ APC pẹ̀lú àwọn olóyè ẹgbẹ́

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:41:15

Bi wọn ṣe fẹnuko naa ni wọn si bura fun awọn alakoso tuntun yii lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.

‘Ìwà ọ̀daràn sí ẹ̀tọ́ ọmọnìyan tó burú jùlọ’: Ṣé ó yẹ káwọn orílẹ̀ èdè tó kó ilẹ̀ Africa san owó gbà mábinú?

'Ìwà ọ̀daràn sí ẹ̀tọ́ ọmọnìyan tó burú jùlọ': Ṣé ó yẹ káwọn orílẹ̀ èdè tó kó ilẹ̀ Africa san owó gbà mábinú?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 13:20:06

Igbimọ aṣofin aajọ ìṣọkan agbaye ti buwọlu kikede fifi awọn eeyan ṣe ẹru gẹgẹ bi iwa ọdaran to buru julọ ti wọn ṣe lati fi tẹ ẹtọ awọn eeyan mọlẹ. Nibi ifẹnuko naa ti wọn ti rọ gbogbo awọn orilẹ ede to ko awọn eeyan lẹru lati da awọn ohun ini awọn eeyan bẹẹ ti wọn ji ko pada.

Wo bí Naijiria, Egypt ṣe ń pàdánù lẹ́ka epo nítorí ogun Iran, tí nǹkan sì ń ṣe ẹnu ire fún South Africa

 Wo bí Naijiria, Egypt ṣe ń pàdánù lẹ́ka epo nítorí ogun Iran, tí nǹkan sì ń ṣe ẹnu ire fún South Africa

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:06:03

Ogun Iran mu ayipada ba iye owo epo ati bi wọn ṣe n gbe epo wọlu, o ko Naijiria ati Egypt ni papamọra ṣugbọn o n la ọna miran ti wọn le gba nipasẹ South Africa.

Ayẹyẹ ọdún Lisabi gbérasọ ní ìlú Abeokuta pẹ̀lú àwọn àkọ̀tun àrà

Ayẹyẹ ọdún Lisabi gbérasọ ní ìlú Abeokuta pẹ̀lú àwọn àkọ̀tun àrà

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:31:01

Bo tilẹ jẹ pe lati ọjọ Aje, ọsẹ yii, ni ayẹyẹ naa ti bẹrẹ pẹlu oniruuru eto ọlọkan-o-jọkan ti wọn ti la kalẹ, ṣugbọn oni ọjọ Abamẹta, ọjọ Kejidinlọgbọn, oṣu Kẹta ni aṣekagba eto naa, nibi ti awọn eeyan pataki ti wọn ti ṣe bẹbẹ ni oniruuru ẹka ti peju lati kopa.

ICPC tú El-Rufai sílẹ̀ lẹ́yìn tó pàdánù ìyá rẹ̀

ICPC tú El-Rufai sílẹ̀ lẹ́yìn tó pàdánù ìyá rẹ̀

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:00:30

Èyí ló ń wáyé lẹ́yìn tí ìròyìn gbòde pé El-Rufai pàdánù ìyá rẹ̀, Hajiya Umma El-Rufai ní ọjọ́ Ẹtí ní ìlú Cairo, orílẹ̀ èdè Egypt.

Ìyá tó bí ìbaàrún ní ìpínlẹ̀ Kano jáde láyé

Ìyá tó bí ìbaàrún ní ìpínlẹ̀ Kano jáde láyé

Ọjọ́ Ẹtì, 27 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:15:01

Ọkunrin mẹta ati obinrin meji lawọn ibarun-un naa ti Eleduwa fi jinki Hafsatu Yusuf, nile iwosan Murtala Specialist hospital lo bi awọn ọmọ naa si ni Kano.

Iran tako ìgbésẹ Amẹrika láti parí ogun tó ń lọ, sọ nǹkan márùn ún tó lè mú wọn dá ogun dúró

Iran tako ìgbésẹ Amẹrika láti parí ogun tó ń lọ, sọ nǹkan márùn ún tó lè mú wọn dá ogun dúró

Ọjọ́ Ẹtì, 27 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 06:49:48

Ṣaaju ni Iran ti sọ pe irọ nla lọrọ ti Aarẹ Donald Trump sọ pe Amẹrika ti n jiroro pẹlu Iran lati pari ogun naa.

Àwa là ń fiyà jẹ ara wa - Okunnu bu ẹnu àtẹ́ lu àwón alágbàtà epo bí owó bẹntiróòlù ṣe gbẹ́nu sókè

Àwa là ń fiyà jẹ ara wa - Okunnu bu ẹnu àtẹ́ lu àwón alágbàtà epo bí owó bẹntiróòlù ṣe gbẹ́nu sókè

Ọjọ́ Ẹtì, 27 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:16:12

Okunnu ní ṣé ìjọba nìkan ló yẹ kí àwọn èèyàn máa báwí lórí ọ̀rọ̀ epo, pé ohun táwọn alágbàtà epo ń ṣe nínú gbogbo ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ yìí náà pọ̀.

Senegal yóò ṣàfihàn Ife ẹ̀yẹ AFCON 2025 lópin ọ̀sẹ̀ yìí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé CAF ti gbé ife náà fún Morocco

Senegal yóò ṣàfihàn Ife ẹ̀yẹ AFCON 2025 lópin ọ̀sẹ̀ yìí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé CAF ti gbé ife náà fún Morocco

Ọjọ́ Ẹtì, 27 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 16:48:14

Lọjọ Aabamẹta ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta yii ni Senegal yoo ṣafihan ife ẹyẹ naa ki ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ ti wọn fẹ gba pẹlu Peru niluu Paris to bẹrẹ.

Àwọn agbébọn kọlu àwọn to ń gbé òkú lọ itẹ́ ní Kwara, yìnbọn pa fijilanté méjì, jí ọ̀kadà àti ìbọn wọn lọ

Àwọn agbébọn kọlu àwọn to ń gbé òkú lọ itẹ́ ní Kwara, yìnbọn pa fijilanté méjì, jí ọ̀kadà àti ìbọn wọn lọ

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:13:03

Lasiko tawọn fijilanté kan lọ ṣe aabo fun awọn to n gbe oku lati ilu Ilorin lọ si ilu Oke-Oyan ni ijọba ibilẹ Ifelodun fun eto isin idagbere la gbọ wi pe awọn agbebọn kọlu wọn, ti wọn si gbẹmi eeyan meji ninu wọn.

Ìdí tí mi ò ṣe kí ń lo ọkọ mi ṣùgbọ́n tí mo máa ń lo ọmọ mi nínú fídíò àwàdà tí mò ń ṣe rèé - Kiekie

Ìdí tí mi ò ṣe kí ń lo ọkọ mi ṣùgbọ́n tí mo máa ń lo ọmọ mi nínú fídíò àwàdà tí mò ń ṣe rèé - Kiekie

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 28 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:16:13

Adẹrinpoṣonu naa sọ pe oun mọọmọ fi aala saarin iṣẹ toun n ṣe ati igbe aye toun n gbe ni.

Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé, orílẹ̀èdè 123, bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ tí yóò sọ òwò ẹrú di ìjìyà tó burú jù lọ fún ọmọnìyàn

Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé, orílẹ̀èdè 123, bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ tí yóò sọ òwò ẹrú di ìjìyà tó burú jù lọ fún ọmọnìyàn

Ọjọ́bọ, 26 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 11:15:28

Igbesẹ ti awọn orilẹede 123 ti fọwọ si yii, awọn ilu bii America, Israel ati Argentina sọ pe awọn ko fara mọ ọn ni tawọn.

Wo bí ìgbẹ́jọ́ àwọn afurasí méje tó dáná sun ilé Asabi Olórìṣà n’Ilọrin ṣe lọ

Wo bí ìgbẹ́jọ́ àwọn afurasí méje tó dáná sun ilé Asabi Olórìṣà n'Ilọrin ṣe lọ

Ọjọ́bọ, 26 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:03:36

Asabi Olorisa ni olujẹjọ keji ti sọ fun oun tẹlẹ pe awọn ti fẹ le oun ni Ilọrin tẹlẹ ṣugbọn tori pe oun ti kọle ni lawọn o ti fii ṣe bẹẹ.

Mo ti bí ọmọ márùn-ún tẹ́lẹ̀ kí n tó bí ibẹ́rin báyìí, ìbejì ni scan sọ fún mi- Ìyá Ìbẹ́rin

Mo ti bí ọmọ márùn-ún tẹ́lẹ̀ kí n tó bí ibẹ́rin báyìí, ìbejì ni scan sọ fún mi- Ìyá Ìbẹ́rin

Ọjọ́ Ajé, 23 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 08:53:41

Nigba ti mo gbọ pe iyawo mi bi ọmọ mẹrin, ẹ ru ba mi, mo si fẹ ṣalọ- Baba Ibẹrin

Mo tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ẹ̀yin ọmọ Naijiria fún iná ọba tí kò sí lásìkò yìí- Adelabu

Mo tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ẹ̀yin ọmọ Naijiria fún iná ọba tí kò sí lásìkò yìí- Adelabu

Ọjọ́rú, 25 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 07:04:49

Adelabu ṣo pe oun paapaa mọ pe ai si ina ọba deede yii n ṣe akoba pupọ fun ọrọ aje awọn eeyan, ka ma ti i sọ ti ooru buruku to n mu lasiko yii lai ṣiwọ.

Èmi ṣì ni alága NURTW- MC Oluomo

Èmi ṣì ni alága NURTW- MC Oluomo

Ọjọ́rú, 25 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:29:09

Ṣáájú ni ìròyìn tí kọ́kọ́ gbòde pé Baruwa àti àwọn èèyàn rẹ̀ yawọ ilé ẹgbẹ́ NURTW tó wà ní Abuja tí wọ́n sì fẹ́ àkóso ilé ẹgbẹ́ náà pé òun ni ilé ẹjọ́ dájọ́ pé òun ó jẹ́ ojúlówó alága ẹgbẹ́ náà.

Ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sí ẹni tí kò bá dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027 rè é - Portable

Ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sí ẹni tí kò bá dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027 rè é - Portable

Ọjọ́rú, 25 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 09:29:02

Nínú fídíò kan tí akọrin náà gbé sójú òpó Instagram rẹ̀ ló ti ń sọ àwọn ọ̀rọ̀ àlùfàńṣà, tó sì ń sọ̀rọ̀ sí àwọn tí kò bání dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027.

‘Biola Bayo, mo fà ẹ́ sí kóòtù Ọlọ́run’-Princess bú sígbe torí Baba Ijesa tí Biola Bayo gbé wá sóri ètò

'Biola Bayo, mo fà ẹ́ sí kóòtù Ọlọ́run'-Princess bú sígbe torí Baba Ijesa tí Biola Bayo gbé wá sóri ètò

Ọjọ́rú, 25 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 10:23:33

Lori ifọrọwerọ naa ni Princess fi tun sọ pe Ọlọrun yoo ṣedajọ fun Biola ati Ijesa, to ba jẹ pe bi eeyan ṣe n ṣe ni wọn ṣe yẹn.

NBA,Ẹgbẹ́ Amòfin Naijiria bínú sí Sowore tó pàtẹ ìpàdé akọ̀ròyìn nínú kóòtù

NBA,Ẹgbẹ́ Amòfin Naijiria bínú sí Sowore tó pàtẹ ìpàdé akọ̀ròyìn nínú kóòtù

Ọjọ́rú, 25 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2026 ní 12:30:11

Ilu Abuja ni iṣẹlẹ naa ti waye lanaa ọjọ Iṣẹgun, nile ẹjọ giga kan.