world-service-rss

BBC News Yorùbá

Èyí ni àpéjọpọ̀ ẹ̀sìn márùn-ún táwọn èèyàn ti máa ń pọ̀jù lágbàáyé

Èyí ni àpéjọpọ̀ ẹ̀sìn márùn-ún táwọn èèyàn ti máa ń pọ̀jù lágbàáyé

Ọjọ́ Àìkú, 12 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 07:54:38

Lọwọlọwọ yii, apejọpọ marun-un lo jẹ koko ti wọn si gbajumọ ju lagbaaye, eyi to jẹ ti ẹsin.

Wo orúkọ àwọn ọmọ Naijiria 124 tí Amẹrika kéde pé àwọn yóò lé kúrò lórílẹèdè náà

Wo orúkọ àwọn ọmọ Naijiria 124 tí Amẹrika kéde pé àwọn yóò lé kúrò lórílẹèdè náà

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 18:59:32

Ọrọ yii lo wa ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ijọba Amẹrika to n ri si ọrọ abẹnu fi lede lori itakun ayelujare wọn.

Èèyàn 161 pàdánù ẹ̀mí wọn láàrin oṣù márùn ún nínú ìjàmbá ọkọ̀ l’Ogun - FRSC

Èèyàn 161 pàdánù ẹ̀mí wọn láàrin oṣù márùn ún nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Ogun - FRSC

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 19:02:12

Agbẹnusọ sọ fun ajọ FRSC ẹka ti ipinlẹ Ogun, Ọgbẹni Afolabi Odunsi, lo fidi ọrọ yii mulẹ fun ileeṣẹ iroyin NAN.

Àwọn ajínigbé de àwọn olùkọ́ ọkùnrin tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso mọ́lẹ̀, wón tún fi aṣọ bò wọ́n lójú fún ọjọ́ mérìndínlọ́gọ́ta - Soun

Àwọn ajínigbé de àwọn olùkọ́ ọkùnrin tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso mọ́lẹ̀, wón tún fi aṣọ bò wọ́n lójú fún ọjọ́ mérìndínlọ́gọ́ta - Soun

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:11:46

Ọba Olaoye lanfaani lati ri awọn akẹẹkọ at’awọn olukọ naa lasiko ti o kan sí ẹka ileeṣẹ ọmogun Naijiria to wa niluu Ibadan nibi ti kabiyesi ti gboṣuba kare fun ọga agba oludari ẹka naa to wa ni agbegbe Ojoo fun iṣẹ takun takun ti wọn ṣe lori bi wọn ṣe doola awọn akẹẹkọ at’awọn olukọ naa.

Ọkọ olùkọ́ tí àwọn agbésùnmọ̀mí ń lò nínú fídíò ìjínigbé Oriire sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ìtúsílẹ̀ ìyàwó rẹ̀

Ọkọ olùkọ́ tí àwọn agbésùnmọ̀mí ń lò nínú fídíò ìjínigbé Oriire sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ìtúsílẹ̀ ìyàwó rẹ̀

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:01:57

Bo tilẹ jẹ pe o ni ijọba ko ti pe oun lati sọ fun oun pe iyawo oun ti wa lakata wọn titi di asiko ti a n ba oun sọrọ amọ inu oun dun.

Ọdún méjìdínlógún ni mo fi wojú Ọlọ́run fọ́mọ kí n tó bí ìbejì - Ricardo Agbor

Ọdún méjìdínlógún ni mo fi wojú Ọlọ́run fọ́mọ kí n tó bí ìbejì - Ricardo Agbor

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:11:20

Ninu ifọrọwerọ kan ti agba oṣere naa ṣe pẹlu AfricanAList lo ti ṣalaye irinajo rẹ ninu sinima ṣiṣe ati igbeaye rẹ lai si ninu sinima.

Ìjọba Nàíjíríà ṣe àfikún lórí owó oṣù àwọn ọmọ ogun láti 49,000 sí 100,000 náírà

Ìjọba Nàíjíríà ṣe àfikún lórí owó oṣù àwọn ọmọ ogun láti 49,000 sí 100,000 náírà

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 11 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:32:30

Ẹgbẹrun lọna ọgọrun kan naira ni ijọba gbe owo oṣu naa si bayii, lati ẹgbẹrun mọkandinlaadọta naira ti wọn n gba tẹlẹ gẹgẹ bi owo oṣu.

“Àkọ̀bí mi tó ń tọ́jú èmi àtàwọn àbúrò rẹ̀ ní wọ́n pa nínú ìjà Hausa àti Yorùbá n’Ibadan”

"Àkọ̀bí mi tó ń tọ́jú èmi àtàwọn àbúrò rẹ̀ ní wọ́n pa nínú ìjà Hausa àti Yorùbá n'Ibadan"

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:38:33

Ounjẹ alẹ ti Habeeb fẹ jẹ la gbọ pe o lọ ra to fi lugbadi iku ojiji ninu ija Yoruba ati Hausa naa

Ẹṣin mọ́kàndínláàádọ́ta ni mo ti pàdánù ní iléeṣẹ́ mi - Ibrahim Chatta

Ẹṣin mọ́kàndínláàádọ́ta ni mo ti pàdánù ní iléeṣẹ́ mi - Ibrahim Chatta

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:50:50

Chatta ninu fidio kan to fi sori ikanni Instagram rẹ, sọ pe oun sọrọ sita lori iṣẹlẹ naa lẹyin ti awọn eeyan n fi oun ṣe yẹyẹ lori ọrọ naa lori ayelujara.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 14:22:50

Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́

Àjọ EFCC wọ́ olórí ẹgbẹ́ Miyetti Allah lọ sílé-ẹjọ́ lórí ẹ̀sun jìbìtì $2.3m

Àjọ EFCC wọ́ olórí ẹgbẹ́ Miyetti Allah lọ sílé-ẹjọ́ lórí ẹ̀sun jìbìtì $2.3m

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:34:20

Ẹsun mejila ọtọọtọ to nii ṣe pẹlu iwa ajẹbanu ni ajọ naa fi kan Miyetti Allah niwaju ile-ẹjọ, eyi ti wọn sọ pe wọn tẹwọ gba obitibiti owo ilẹ okeere ọhun, ti wọn lo lodi si ofin.

Amẹ́ríkà àti Iran tún ju àdó olóró síra, èèyàn mẹ́rìnlá jáde láye

Amẹ́ríkà àti Iran tún ju àdó olóró síra, èèyàn mẹ́rìnlá jáde láye

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:12:59

Amẹrika ni awọn ṣe ikọlu si ibudo awọn oloogun Iran to jẹ aadọrun-un. Iran sọ pe eeyan mẹrinla ni Amẹrika ti pa lẹnu ikọlu ọjọ meji naa.

Ìjìyà tó bá tọ́ sí agbésùnmọ̀mí la máa fún ṣọ́jà tó bá ń dúró de àṣẹ kó tó pa wọ́n- Mínísítà ètò ààbò

Ìjìyà tó bá tọ́ sí agbésùnmọ̀mí la máa fún ṣọ́jà tó bá ń dúró de àṣẹ kó tó pa wọ́n- Mínísítà ètò ààbò

Ọjọ́ Ẹtì, 10 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:14:52

Ipinlẹ Sokoto ni Ọgagun Musa ti sọrọ yii, lasiko ti wọn n pin awọn ọkọ akọtami fawọn ẹka alaabo .

Aṣojú ìjọba Nàìjíríà nílẹ̀ Olómìnira Benin gba àlejò ọkùnrin tó gun ọ̀kadà láti London wá sí Nàìjíríà

Aṣojú ìjọba Nàìjíríà nílẹ̀ Olómìnira Benin gba àlejò ọkùnrin tó gun ọ̀kadà láti London wá sí Nàìjíríà

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:23:22

Ọjọ kejila, oṣu Kẹfa ọdun 2026 yii ni Olatunji Emmanuel Okedeyi gbera kuro niluu London.

Àwọn afurasí tò ṣekúpa òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì OGTV fojú ba ilé ẹjọ́, bí ìgbẹ́jọ́ ṣe lọ rèé

Àwọn afurasí tò ṣekúpa òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì OGTV fojú ba ilé ẹjọ́, bí ìgbẹ́jọ́ ṣe lọ rèé

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:15:56

Kitan Oyesiku ati ẹṣọ alaabo rẹ, Pelumi Adetayo ni awọn amookunṣeka naa pa nipakupa laipẹ yii niluu Kobape to wa loju ọna marosẹ Abeokuta si Sagamu.

Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo gbẹ̀mí afurasí ajínigbé méjì lójú ọ́nà Owo lẹ́yìn tí wọ́n ṣíná ìbọn fúnra wọn

Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo gbẹ̀mí afurasí ajínigbé méjì lójú ọ́nà Owo lẹ́yìn tí wọ́n ṣíná ìbọn fúnra wọn

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:38:49

Ọlọpaa ni awọn ri ibọn ilewọ agbelẹrọ meji, ọta ibọn, awọn iboju meji, ẹrọ ilewọ ati kaadi ATM lakata wọn lẹyin ikọlu naa.

Mo lè má sí láyé láti kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2027 – Obi

Mo lè má sí láyé láti kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2027 – Obi

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:53:38

Gomina tẹlẹri nipinlẹ Anambra sọ pe ọpọ awọn ẹtọ oun ni ijọba ilẹ Naijiria fi n dunkooko mọ oun, ati pe gbogbo awọn to duro gẹgẹ bi alatako ijọba ni wọn n dojukọ idunkooko loriṣiriṣi.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Agbèsùnmọ̀mí pa ṣọ́já, dàná sun àgọ́ ọlọ́pàá, iléèwòsàn àti yàrá ìkàwé

Agbèsùnmọ̀mí pa ṣọ́já, dàná sun àgọ́ ọlọ́pàá, iléèwòsàn àti yàrá ìkàwé

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 09:58:35

Adele Alukoro fun ẹka ologun apapọ lapa Ariwa-Ila-Oorun Naijiria, Ọgagun Muhammed Goni, fidi ikọlu naa mulẹ ninu atẹjade to fi sita l’Ọjọbọ, ọjọ kẹsan-an oṣu Keje ọdun 2026 yii.

Ẹ má ṣe kọ̀ láti gba ọgọ́rùn-ún kan náírà, ìjìyà wà fún ẹni tó bá kọ̀ ọ́ – Báǹkì àpapọ̀ Naijiria kìlọ̀ fùn aráàlú

Ẹ má ṣe kọ̀ láti gba ọgọ́rùn-ún kan náírà, ìjìyà wà fún ẹni tó bá kọ̀ ọ́ – Báǹkì àpapọ̀ Naijiria kìlọ̀ fùn aráàlú

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 15:17:30

CBN sọ pe ki gbogbo awọn to n kọ lati maa gba owo ọgọrun kan naira naa dẹkun iwa naa bayii, nitori pe owo ọhun ṣi n jẹ itẹwọgba labẹ aṣẹ, akoso ati ofin ilẹ Naijiria.

Báwo ni owó PFIPC ṣe wọ́ àbá ìsúná tó bá jẹ́ ìjọba kò mọ nípa àjọ náà lóòótọ́, èmi kọ́ ni mo ṣé e, mo wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá lásìkò náà - Adeyemi sọ nínú fídíò tuntun

Báwo ni owó PFIPC ṣe wọ́ àbá ìsúná tó bá jẹ́ ìjọba kò mọ nípa àjọ náà lóòótọ́, èmi kọ́ ni mo ṣé e, mo wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá lásìkò náà - Adeyemi sọ nínú fídíò tuntun

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 05:46:10

Ninu fidio kan to gba ori ayelujara ṣafihan bi Adeyemi ṣe n ba gbajumọ ori ayelujara, Martins Otse ti ọpọ eeyan mọ si VeryDarkMan sọrọ.

Ifá kìlọ̀ fáwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò gómìnà l’Osun, àlàyè rèé

Ifá kìlọ̀ fáwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò gómìnà l'Osun, àlàyè rèé

Ọjọ́bọ, 9 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:33:08

Ẹgbẹ naa ti orukọ wọn n jẹ Traditional Religion Worshippers Association of Osun State (TRAWSO), ṣekilọ yii lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Oṣogbo lọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii.

Wo ìdí tí ICPC fi mú dókítà tó ń tọ́jú El-Rufai àti bí aya rẹ̀ ṣe ń rọ Tinubu pé kó rántí àjọṣepọ̀

Wo ìdí tí ICPC fi mú dókítà tó ń tọ́jú El-Rufai àti bí aya rẹ̀ ṣe ń rọ Tinubu pé kó rántí àjọṣepọ̀

Ọjọ́rú, 8 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:55:19

Ẹ o ranti pe El-Rufai ti wa ni gbaga ijọba lati oṣu keji ọdun 2026 lori ẹsun ajẹbanu atawọn mi-in tijọba apapọ n ba a fa.

Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò

Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò

Ọjọ́rú, 8 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:40:36

Gẹgẹ bi awọn ẹka ẹṣọ aabo ṣe n fidi ẹ mulẹ, wọn ni ẹkọ ti n fi oju mimu han lẹyin ti wọn ti mọ awọn to wa nidii ijinigbe naa, atawọn alajọṣiṣẹ pọ wọn.

Ìjọba àpapọ̀ kéde ìpínlẹ̀ 26 tí òjò àrọ̀rọ̀dá yóò ti wáyé fún ọ̀sẹ̀ méjìlá èyí tí yóò fa ẹ̀kún omi

Ìjọba àpapọ̀ kéde ìpínlẹ̀ 26 tí òjò àrọ̀rọ̀dá yóò ti wáyé fún ọ̀sẹ̀ méjìlá èyí tí yóò fa ẹ̀kún omi

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 09:16:09

Adari ajọ NiHSA Umar Mohammed, ni awọn ti kilọ fun awọn ọmọ Naijiria ṣaaju iṣẹlẹ ọhun amọ gbogbo ikilọ awọn ni araalu kọ eti ọgbọin si.

Ọmọ ọdún méjìlélógún ṣàlàyé bó ṣe jí ara rẹ̀ gbé, tó sì ń bèèrè N25m owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ẹbí rẹ̀

Ọmọ ọdún méjìlélógún ṣàlàyé bó ṣe jí ara rẹ̀ gbé, tó sì ń bèèrè N25m owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ẹbí rẹ̀

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:04:45

James ninu fidio kan ti Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Delta, Bright Edafe fi sita lọjọ Aiku, ṣalaye pe oun mọ-ọn-mọ wọgbo lọ, oun si pe iya oun lori aago pe wọn ti ji oun gbe.

Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ

Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:45:57

Ọlọpaa sọ pe ikọlu ti eegun naa atawọn ọmọ ẹyin rẹ si si ọkunrin naa lo pa a lọjọ Aiku, ọjọ karun-un oṣu Keje ọdun 2026.

IMF fẹ̀sùn kan ìjọba àpapọ̀ pé ó ná ₦N8.83trn tí kò ní àkọsílẹ̀, ìjọba ṣẹ́, Peter Obi àti Atiku ní kí Tinubu fi ipò sílẹ̀

IMF fẹ̀sùn kan ìjọba àpapọ̀ pé ó ná ₦N8.83trn tí kò ní àkọsílẹ̀, ìjọba ṣẹ́, Peter Obi àti Atiku ní kí Tinubu fi ipò sílẹ̀

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:40:05

Aṣoju ajọ IMF ni Naijiria, Christian Ebeke, sọ niluu Eko pe nnkan bii ida meji owo ti ijọba Naijiria na ni ko si akọsilẹ rẹ rara, bo tilẹ jẹ pe o yẹ ki akọsilẹ rẹ wa.

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Sam Larry níbi tí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ Adewale ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Sam Larry níbi tí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ Adewale ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 05:56:32

Ninu ibanujẹ ọkan ni ẹbi Adewale, ẹṣọ Sam Larry to ku ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lopopona marosẹ Eko si Calabar wa bayii.

Davido ṣàlàyé ìdí tó fi wọ aṣọ tórúkọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso wà lára rẹ̀ níbí ìdíje World Cup

Davido ṣàlàyé ìdí tó fi wọ aṣọ tórúkọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso wà lára rẹ̀ níbí ìdíje World Cup

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 07:56:58

Davido sọ fun BBC News Africa wi pe ko ṣee ṣe ki oun kọ eti ikun si eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria papaa julọ ijinigbe awọn akẹkọọ mọkandinlogoji atawọn olukọ meje to ṣẹlẹ ni ijọba ibilẹ Oriire nipinlẹ Oyo.

Mo ta ‘Pure Water’ láti rán ara mi nílé ẹ̀kọ́ àmọ́ ń kò parí rẹ̀, èmi tí wọ́n ń pè ní Olódo tẹ́lẹ̀, ló ń bọ́ bàbá àti ẹbí mi báyìí - Portable

Mo ta ‘Pure Water’ láti rán ara mi nílé ẹ̀kọ́ àmọ́ ń kò parí rẹ̀, èmi tí wọ́n ń pè ní Olódo tẹ́lẹ̀, ló ń bọ́ bàbá àti ẹbí mi báyìí - Portable

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:21:29

Portable sọrọ yii ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti o ṣe pẹlu awọn akọroyin ori itakun ayelujara.

Awuyewuye bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn tí àdó olóró pa ọmọ Nàíjíríà tó n kẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ ìṣègùn òyìnbó ní Ukraine

Awuyewuye bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn tí àdó olóró pa ọmọ Nàíjíríà tó n kẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ ìṣègùn òyìnbó ní Ukraine

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:51:43

Nnani la gbọ pe o ki aye pe o digboṣe lẹyin to fara kaaṣa ado oloro ti awọn ọmọ ogun orileede Russia ju si ilẹ Ukraine lasiko ikọlu.

Kí ni àyájọ́ 7-7 túmọ̀ sí àti itú tàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn le pa láti sàmì àyájọ́ náà

Kí ni àyájọ́ 7-7 túmọ̀ sí àti itú tàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn le pa láti sàmì àyájọ́ náà

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 7 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:18:15

Atẹjade ti ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ati Osun fisita lori ayajọ ẹgbẹ okunkun 7-7, ti wa n sin awọn araalu ni gbẹrẹ ipakọ pe ki wọn fura nipa ọsẹ tawọn ẹlẹgbẹ okunkun naa le se.okunkun naa le se.

Ojú mi rí màbo láti kékeré títí mo fi délé ọkọ, mo fẹ́ pa ègún, tó ja ìyá mi àti èmi rẹ́ lórí ọmọ - Iyabo Ojo

Ojú mi rí màbo láti kékeré títí mo fi délé ọkọ, mo fẹ́ pa ègún, tó ja ìyá mi àti èmi rẹ́ lórí ọmọ - Iyabo Ojo

Ọjọ́rú, 8 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:09:40

Iyabo Ojo ṣalaye pe ipinya oun ati ọkọ toun bimọ fun ko kan awọn tawọn bi.

Wo ìlú márùn-ún tí ètò ìsìnkú Ayatollah Khamenei, olórí Iran tí US pa yóò ti wáyé fún ọjọ́ mẹ́fà

Wo ìlú márùn-ún tí ètò ìsìnkú Ayatollah Khamenei, olórí Iran tí US pa yóò ti wáyé fún ọjọ́ mẹ́fà

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 4 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 14:46:55

Gẹgẹ bi wọn ṣe kede, o kere tan, isinku naa yoo gba wọn to ọjọ mẹfa.

Mi ò kìí ṣe olè, àkóbá òṣèlú ni wọ́n ṣe fún mi - Surii Ilupeju

Mi ò kìí ṣe olè, àkóbá òṣèlú ni wọ́n ṣe fún mi - Surii Ilupeju

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:21:05

Ẹ o ranti pe bii ọsẹ mẹta sẹyin ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe afurasi adigunjale ni Surii Ilupeju ati pe ọpọ awọn ohun ija oloro bii ibọn atawọn nnkan mii ni awọn ba ninu ile rẹ nigba ti awọn ṣabẹwo sibẹ.

A ti pa púpọ̀ nínú àwọn agbésùnmọ̀mí tó kọlu ilú márùn- ún -Iléeṣẹ́ ọmọ ogun

A ti pa púpọ̀ nínú àwọn agbésùnmọ̀mí tó kọlu ilú márùn- ún -Iléeṣẹ́ ọmọ ogun

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:00:11

Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ologun Mali fi sita ni wọn ti ṣalaye, pe alaafia ti jọba ni ilu marun-un ti awon agbesunmọmin naa dojukọ.

Ẹ wo ìlúbìnrin tó gbajúmọ̀ tí kò fi ààyè gba ọkùnrin láti máa gbé níbẹ̀

Ẹ wo ìlúbìnrin tó gbajúmọ̀ tí kò fi ààyè gba ọkùnrin láti máa gbé níbẹ̀

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:04:07

Ọdun 1990 ni obìnrin mẹẹdogun kan da abule naa silẹ, lẹyin ti wọn bọ lọwọ awọn ọmọ ogun ilẹ Gẹẹsi to n fi ipa ba wọn lo pọ.

Olórí ọmogun Naijiria ṣàlàyé ibi tí iṣẹ́ dé lori ìgbìyànjú láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso

Olórí ọmogun Naijiria ṣàlàyé ibi tí iṣẹ́ dé lori ìgbìyànjú láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:26:35

Lọjọ kẹẹdọgbọn oṣù Karun un lawọn janduku agbébọn yawọ ile ẹkọ girama to wa ni Esinele ati ile ẹkọ alakọbẹrẹ ni Yawota ní ìjọba ìbílẹ̀ Oriire; nibi ti wọn ti ji àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ to le logoji lọ.

Ìjọba bu ẹnu àtẹ́ lu pípa àwọn ọmọ Nàìjíríà méjì ní South Africa bí ìjọba South Africa ṣe kéde ṣíṣe àtìlẹyìn fáwọn tí okoòwò wọn bá ìwọ́de lọ

Ìjọba bu ẹnu àtẹ́ lu pípa àwọn ọmọ Nàìjíríà méjì ní South Africa bí ìjọba South Africa ṣe kéde ṣíṣe àtìlẹyìn fáwọn tí okoòwò wọn bá ìwọ́de lọ

Ọjọ́ Àìkú, 5 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 17:08:03

Atẹjade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ to n ri si eto irinna silẹ okeere, Imomotimi Ebienfa fi lede lọjọ Karun-un, oṣu Keje sọ pe awọn eeyan to padanu ẹmi wọn naa ni Emeka Charles Ibegbeu ati Nnaemeka Mathew Andrew Ekepynong.

Àwọn agbébọn ṣèkọlù sáwọn àgbẹ̀ nínú oko, pa mẹ́sàn-án, jí ọ̀pọ̀ gbé lọ

Àwọn agbébọn ṣèkọlù sáwọn àgbẹ̀ nínú oko, pa mẹ́sàn-án, jí ọ̀pọ̀ gbé lọ

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:04:50

Gẹgẹ bi awọn araalu ti ikọlu naa ṣoju wọn ṣe sọ, ikọlu naa waye nigba ti awọn agbebon meji kan fẹ gbiyanju lati ja ọkada agbẹ kan gba.

“N25.5m, àpò ìrẹsì, epo pẹtiró àtàwọn nńkan míì ni ajínigbé gbà lọ́wọ́ wa, káwọn èèyàn wa ní Eda Oniyo tó gba ìtúsílẹ̀, Irọ́ ni, àwa ọlọ́pàá, ológun, Àmọ̀tẹ́kùn ló gbà wọ́n sílẹ̀”

"N25.5m, àpò ìrẹsì, epo pẹtiró àtàwọn nńkan míì ni ajínigbé gbà lọ́wọ́ wa, káwọn èèyàn wa ní Eda Oniyo tó gba ìtúsílẹ̀, Irọ́ ni, àwa ọlọ́pàá, ológun, Àmọ̀tẹ́kùn ló gbà wọ́n sílẹ̀"

Ọjọ́ Ajé, 6 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:33:28

Miliọnu mẹwaa aabọ naira ni araalu kọkọ san fun awọn ajinigbe naa, ki wọn to fi mẹwaa miran-an kun un bi wọn ṣe sọ.