world-service-rss

BBC News Yorùbá

Èèyàn 12 kú báwọn sọ́jà ṣe ju àdó olóró, àmọ́ iléeṣẹ́ ológun ní agbébọn ni àwọn pa

Èèyàn 12 kú báwọn sọ́jà ṣe ju àdó olóró, àmọ́ iléeṣẹ́ ológun ní agbébọn ni àwọn pa

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:22:54

Onoja ni ileeṣẹ Ologun ṣe iwadii wọn daadaa ti awọn si fidi rẹ mulẹ pe awọn agbebọn n fi ilu Lukupe atawọn ilu mii ni ijọba ibilẹ Shiroro, ipinlẹ Niger ṣe ibugbe ki awọn to lọ ṣekọlu si wọn.

Àlàyé rèé lórí ohun fà á táwọn òṣìṣẹ́ tó ń pèsè omi àti ètò ọ̀gbìn ṣe gunle ìyánṣẹ́lódì

Àlàyé rèé lórí ohun fà á táwọn òṣìṣẹ́ tó ń pèsè omi àti ètò ọ̀gbìn ṣe gunle ìyánṣẹ́lódì

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:06:00

Akọroyin BBC News Yoruba wa nibi iwọde naa, to si bawọn osisẹ, alasẹ ileeẹsẹ ati awọn adari ẹgbẹ osisẹ nipinlẹ Kwara sọrọ lati mọ ohun to sokunfa iwọde naa.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:46:58

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

“Eré ìdárayá ìgbátí ni mo fi ń jẹun, wọ́n ti gbá mi léti rí tí ojú mi ya, mo sojú Nàíjíríà nínú ìdíje àgbáyé”

"Eré ìdárayá ìgbátí ni mo fi ń jẹun, wọ́n ti gbá mi léti rí tí ojú mi ya, mo sojú Nàíjíríà nínú ìdíje àgbáyé"

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:06:32

BBC News Yoruba kan si ọkunrin kan, Kabiru Adediran to n fi ere idaraya ìgbátí jẹun láti mọ bí eré ìdárayá náà ti gbajúmọ̀ sí àti ọ̀pọ̀ ewu tó rọ̀ mọ́ ọ.

Kí ló mú kí ọkọ̀ kan ré bọ́ láti orí afárá sí ìsàlẹ̀ èyí tó pa èèyàn mọ́kànlá l‘Ogun?

Kí ló mú kí ọkọ̀ kan ré bọ́ láti orí afárá sí ìsàlẹ̀ èyí tó pa èèyàn mọ́kànlá l‘Ogun?

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:51:02

FRSC ṣalaye pe ọkọ Toyota kan ti nọmba rẹ jẹ GGE722KJ gbe okiti ni ẹẹmẹta ko to di pe o jabọ lati ori afara to wa.

Àlàyé rèé lórí ohun táwọn iléeṣẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ ṣe tí ìjọba àpapọ̀ ṣe fọnmú mọ́ wọn lọ́wọ́

Àlàyé rèé lórí ohun táwọn iléeṣẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ ṣe tí ìjọba àpapọ̀ ṣe fọnmú mọ́ wọn lọ́wọ́

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:45:43

Ijọba ti gbe awon igbesẹ to laami-laaka fun atunṣe ikansira ẹni gẹgẹ bi Minisita eto ikansira ẹni ṣe sọ.

“Eko Bridge yóò wà ní títìpa fún àtúnṣe láti ọjọ́ Ìṣẹ́gun” -Ìjọba Eko

"Eko Bridge yóò wà ní títìpa fún àtúnṣe láti ọjọ́ Ìṣẹ́gun" -Ìjọba Eko

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:46:46

Eredi titipa naa bi wọn wi ni fun atunṣe, aabo ati iwadii

Èèyàn mẹ́ta tí ẹ̀yà ara pè níjà bọ́ sọ́wọ́ NDLEA fún ẹ̀sùn òògùn olóró

Èèyàn mẹ́ta tí ẹ̀yà ara pè níjà bọ́ sọ́wọ́ NDLEA fún ẹ̀sùn òògùn olóró

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:53:39

Femi Babafemi ti i ṣe Adari ikede ni NDLEA, ṣalaye ninu atẹjade naa pe baba agba ẹni ọgọta ọdun (60), torukọ rẹ n jẹ Romanus Nwabara, wa lara awọn akanda ẹda ti ọwọ ba fun ẹsun naa.

Ọkọ ojú omi tí wọ́n ti ṣàwárí ààrùn hantavirus balẹ̀ sí Spain, àyẹ̀wò bẹ̀rẹ̀ fáwọn èrò

Ọkọ ojú omi tí wọ́n ti ṣàwárí ààrùn hantavirus balẹ̀ sí Spain, àyẹ̀wò bẹ̀rẹ̀ fáwọn èrò

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:12:57

Minisita feto ilera Spain, Mónica Gracía sọ pe bí wọn ṣe n ko awọn eeyan bọlẹ ninu ọkọ naa lo n lọ ni mẹsọmẹsọ amọ gbogbo awọn eeyan to wa ninu ọkọ oju omi MS Hondius ni ko ṣoju pe ohunkohun n ṣe wọn.

Lateef Adedimeji, Oboz, àtàwọn òṣèré míì tó gbàmì ẹ̀yẹ ní AMVCA 2026

Lateef Adedimeji, Oboz, àtàwọn òṣèré míì tó gbàmì ẹ̀yẹ ní AMVCA 2026

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:11:52

Ni alẹ ọjọ Abamẹta, ọjọ Kẹsan-an, oṣu Karun-un ni ayẹyẹ naa, to jẹ ikejila iru rẹ waye ni ipinlẹ Eko nibi ti ọpọ awọn agbjumọ oṣere tiata kaakiri ilẹ Africa pejupese si.

EFCC kéde wíwá Sadiya Farouq, mínísítà tẹ́lẹ̀ fún ètò ìbojú-àánú wo aráàlú

EFCC kéde wíwá Sadiya Farouq, mínísítà tẹ́lẹ̀ fún ètò ìbojú-àánú wo aráàlú

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:20:13

Awọn ẹsun bii kiko owo ilu si apo ara ẹni, aṣilo ipo ati igbimọ pọ huwa ọdaran ni EFCC kede pe oun n wa Sadiya Farouq fun.

Ẹgbẹ́ NDC kéde ipò ààrẹ sí Gúúsù Naijiria ní 2027, 2031 fún Àríwá

Ẹgbẹ́ NDC kéde ipò ààrẹ sí Gúúsù Naijiria ní 2027, 2031 fún Àríwá

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 18:15:03

Ikede yii waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹsan-an oṣu Karun-un ọdun 2026, nibi ipade apapọ ẹgbẹ NDC to waye niluu Abuja.

Kí ló mú kí ọkọ̀ kan ré bọ́ láti orí afárá sí ìsàlẹ̀ èyí tó pa èèyàn mọ́kànlá l‘Ogun?

Kí ló mú kí ọkọ̀ kan ré bọ́ láti orí afárá sí ìsàlẹ̀ èyí tó pa èèyàn mọ́kànlá l‘Ogun?

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:51:02

FRSC ṣalaye pe ọkọ Toyota kan ti nọmba rẹ jẹ GGE722KJ gbe okiti ni ẹẹmẹta ko to di pe o jabọ lati ori afara to wa.

Kí ló fa òórùn àbaadì tó kó aráàlú lọ́kàn sókè l’Ado Ekiti? Àlàyé rèé

Kí ló fa òórùn àbaadì tó kó aráàlú lọ́kàn sókè l'Ado Ekiti? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:58:16

Ohun to tilẹ le ni pe wọn ko le sọ pato apa ibi ti oorun naa ti n fẹ wa, bẹẹ o kari gbogbo agbegbe.

Ta ló ń wó pátákó ìpolongo Gómìnà Adeleke lulẹ̀ l’Osun tí APC àti Accord Party fi ń ju òkò ọ̀rọ̀ sí ara wọn?

Ta ló ń wó pátákó ìpolongo Gómìnà Adeleke lulẹ̀ l'Osun tí APC àti Accord Party fi ń ju òkò ọ̀rọ̀ sí ara wọn?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:32:07

Ṣaaju ni iroyin sọ pe ikọ ipolongo ibo Gomina Ademola Adeleke ti fẹsun kan ẹgbẹ oṣelu APC pe wọn n ran awọn janduku lati maa ba awọn atẹ ipolongo ẹgbẹ oṣelu Accord Party jẹ kaakiri ipinlẹ Osun.

Amotekun nawọ́ gán afurasí agbéṣùmọ̀mí ní ìpínlẹ̀ Ondo

Amotekun nawọ́ gán afurasí agbéṣùmọ̀mí ní ìpínlẹ̀ Ondo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:57:31

Adeleye sọ pe ọwọ tẹ awọn afurasi naa lasiko tawọn Amotekun ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ẹṣọ aabo mii latari italolobo kan ti wọn gbọ.

Lateef Adedimeji kéde orúkọ àwọn ìbẹ́ta rẹ àti ọjọ́ tí wẹ̀jẹwẹ̀mu ìdúpẹ́ yóò wáyé

Lateef Adedimeji kéde orúkọ àwọn ìbẹ́ta rẹ àti ọjọ́ tí wẹ̀jẹwẹ̀mu ìdúpẹ́ yóò wáyé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:33:03

Lateef Adedimeji ni aworan awọn ọmọ kan tawọn kan n gbe kaakiri ori ayelujara ti wọn n pe ni ọmọ oun kii ṣe ọmọ oun o, bi asiko ba to oun ati iyawo oun yoo fi fọto awọn ọmọ naa sita.

Ta ni Stanley Osifo tó fẹ́ kojú Tinubu níbi ètò ìdìbò abẹ́nú APC?

Ta ni Stanley Osifo tó fẹ́ kojú Tinubu níbi ètò ìdìbò abẹ́nú APC?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:58:23

Bayii ọkunrin kan ti jade, to si ti ra fọọmu lati dije tako Tinubu nibi eto idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu APC to n bọ nibi ti wọn ti maa yan awọn to gbe asia ẹgbẹ oṣelu naa nibi eto idibo gbogbogbo ọdun 2027.

Kí ló dé tí ọ̀pọ̀ àwọn tó ń bá Gómìnà Seyi Makinde ṣiṣẹ́ níjọba ìpínlẹ̀ Oyo ń kọ̀wé fipò sílẹ̀?

Kí ló dé tí ọ̀pọ̀ àwọn tó ń bá Gómìnà Seyi Makinde ṣiṣẹ́ níjọba ìpínlẹ̀ Oyo ń kọ̀wé fipò sílẹ̀?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:42:25

‎Ohun ti ọpọ awọn to ti kọwe fipo silẹ sọ ni wi pe ija to wa ninu ẹgbẹ oṣelu PDP yoo ṣe idiwo fun awọn ninu eyo idibo to n bọ.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Hantavirus: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àjàkálẹ̀ àrùn tuntun tó ṣẹ́yọ, àti bí o ṣe lè dáàbò bo ara rẹ

Hantavirus: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àjàkálẹ̀ àrùn tuntun tó ṣẹ́yọ, àti bí o ṣe lè dáàbò bo ara rẹ

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:39:51

WHO sọ fun BBC pe ‘‘iwadii kikun si n lọ lọwọ lori awọn eeyan tawọn fura si pe wọn ni arun ọhun.’’

Omoyele Sowore tún fojú balé ẹjọ́ lónìí lórí ẹ̀sùn pé ó pe Ààrẹ Tinubu ní ọ̀daràn, ohun tó bá bọ̀ rèé

Omoyele Sowore tún fojú balé ẹjọ́ lónìí lórí ẹ̀sùn pé ó pe Ààrẹ Tinubu ní ọ̀daràn, ohun tó bá bọ̀ rèé

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 16:39:09

Ti ẹ ko ba gbagbe, adajọ yii lo ni ki agbẹjọro Sowore kunlẹ nile ẹjọ loṣu to kọja.

Wọ́n bá òkú ọmọ ọdún mọ́kànlélógún nínú yàrá l’Osun, ariwo sọ

Wọ́n bá òkú ọmọ ọdún mọ́kànlélógún nínú yàrá l'Osun, ariwo sọ

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:13:23

Ọbẹ ati nnkan kan to wa ninu ike kekere kan ni wọn ba lẹgbẹẹ oloogbe naa, ṣugbọn wọn ko mọ bo ya mọjele ni abi bẹẹ kọ.

Kí ló mú Davido ṣẹ́wélé orin kíkọ fún oṣù méjì báyìí? Àlàyé rèé

Kí ló mú Davido ṣẹ́wélé orin kíkọ fún oṣù méjì báyìí? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:00:29

Davido ṣalaye pe oun gbe igbesẹ yii lati ṣe ipolongo ibo fun Gomina Ademola Adeleke to fẹ dupo gomina ipinlẹ fun saa keji.

Egúngun tó lé obìnrin kan láì dẹ̀yìn jìyà àjẹpọ́nnulá; Obìnrin náà ṣíṣọ lójú rẹ̀ níta gbangba ló bá di ọkọ rẹ̀

Egúngun tó lé obìnrin kan láì dẹ̀yìn jìyà àjẹpọ́nnulá; Obìnrin náà ṣíṣọ lójú rẹ̀ níta gbangba ló bá di ọkọ rẹ̀

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:08:17

Egungun ti iṣẹlẹ abuku naa kan ni wọn pe orukọ rẹ ni Omebe, a gbọ pe egungun to fẹran jagidijagan ni.

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá VCRU tuntun, ìdí fún ìdásílẹ̀ rẹ̀ àti iṣẹ́ àwọn ọlọ́pàá náà

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá VCRU tuntun, ìdí fún ìdásílẹ̀ rẹ̀ àti iṣẹ́ àwọn ọlọ́pàá náà

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:46:10

Ọga ọlọpaa ṣe ifilọlẹ naa lasiko to bawọn lọgalọga ọlọpaa ṣepade pọ niluu Abuja lana ọjọ Iṣẹgun ọjọ karun un oṣu Karun un yii.

Ọba Adeyemi Adediran, Owamiran ti ìlú Esa-oke wàjà

Ọba Adeyemi Adediran, Owamiran ti ìlú Esa-oke wàjà

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 18:10:35

‎Ninu atẹjade ti Rasheed Olawale, ẹni to jẹ agbẹnusọ fun gomina Ademola Adeleke lede lo ti fidi rẹ mulẹ pe Ọba Adeyemi Adediran, Owamiran ti iluu Esa-oke ti waja.

Bàbá Mohbad fẹ́ jogún ọmọ rẹ̀; mi ò lè fun ní ohun tó ń fẹ́ – Wumi Aloba

Bàbá Mohbad fẹ́ jogún ọmọ rẹ̀; mi ò lè fun ní ohun tó ń fẹ́ – Wumi Aloba

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 16:33:17

Wumi lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu ileeṣẹ iroyin Channels.

Kí ló fa gbas-gbos láàárín Akpabio àti Oshiomhole nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin, àlàyé rèé

Kí ló fa gbas-gbos láàárín Akpabio àti Oshiomhole nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin, àlàyé rèé

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:18:52

Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, o to iṣẹju mẹwaa ti aigbọra ẹni ye to waye laaarin awọn mejeeji fi ṣẹlẹ, lẹyin naa si ni ipade ṣẹṣẹ bẹrẹ pada.

Ohun tó dùn mi jùlọ láyé lọ̀rọ̀ tí ìyàwó mi sọ pé méjì nínú ọmọ márùn ún tí mo ṣe súná wọn kìí ṣe tèmi - Òṣèré tíátà, Tioruju

Ohun tó dùn mi jùlọ láyé lọ̀rọ̀ tí ìyàwó mi sọ pé méjì nínú ọmọ márùn ún tí mo ṣe súná wọn kìí ṣe tèmi - Òṣèré tíátà, Tioruju

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:00:20

Nigba to n sọrọ ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu African A List, Tioruju ṣalaye bi o ti pada sile lati ibi to ti lọ ṣe ere ori itage, ti ko si ba iyawo rẹ ti oyun ọmọ karun un wọn wa ninu rẹ.

Ọkùnrin méje tó ṣe pàṣí-pààrọ̀ ìyàwó bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá Hisbah

Ọkùnrin méje tó ṣe pàṣí-pààrọ̀ ìyàwó bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá Hisbah

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:49:26

Ẹka Hisbah ipinlẹ Bauchi ṣalaye pe agbegbe Azare, nijọba ibilẹ Katagum, ni ọwọ ti ba awọn baale ile meje ti wọn ni wọn n paarọ iyawo naa.

A ò tíì wẹ̀ láti ọjọ́ mẹ́ta, kò sí ìná, kò sí omi – Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ibadan figbe ta

A ò tíì wẹ̀ láti ọjọ́ mẹ́ta, kò sí ìná, kò sí omi – Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ibadan figbe ta

Ọjọ́rú, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 17:24:57

Eredi ifọhẹhonuhan naa ko ṣẹyin inira wọn lẹyin iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ ti kii ṣe olukọni, NASU, ninu ile ẹkọ ọhun to n lọ lọwọ.

Ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin 19 darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú NDC

Ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin 19 darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú NDC

Ọjọ́rú, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:49:14

Lọjọ Iṣẹgun lawọn aṣojuṣofin naa kede igbesẹ wọn ninu ile naa.

Bí ìjọba bá tọwọ́ bọ̀wé láti ṣe ẹ̀tọ́ tí wọ́n ṣe fáwọn ASUU fún àwa náà la tó máa dẹ́kun ìyanṣẹ́lódì wa - SSANU, NASU, NAAT

Bí ìjọba bá tọwọ́ bọ̀wé láti ṣe ẹ̀tọ́ tí wọ́n ṣe fáwọn ASUU fún àwa náà la tó máa dẹ́kun ìyanṣẹ́lódì wa - SSANU, NASU, NAAT

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:52:26

Iyanṣẹlodi yii lọ n waye jakejado gbogbo faṣiti ati ile iwe gbogbo nise to jẹ ti ìjọba apapọ to ri lẹ ede yii.

Sisi Alagbo bẹ àwọn abiyamọ ayé àti ẹgbẹ́ alágbo, ó ní òun ti ṣe àṣìṣe ńlá

Sisi Alagbo bẹ àwọn abiyamọ ayé àti ẹgbẹ́ alágbo, ó ní òun ti ṣe àṣìṣe ńlá

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 17:46:05

Ninu fidio mii to tun fi lede loju opo Facebook rẹ lọjọ Aje ọsẹ yii ni Sisi Alagbo ti kunlẹ to si n wa ẹkun mu bo ṣe n bẹbẹ fun aforiji lọwọ awọn ololufẹ rẹ, mọlẹbi rẹ atawọn ọmọ Naijiria.

Ọkùnrin tí wọ́n sinòkú rẹ padà wọ ìlú, ariwo sọ

Ọkùnrin tí wọ́n sinòkú rẹ padà wọ ìlú, ariwo sọ

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:47:36

Ileeṣẹ iroyin Daily Monitor jabọ pe, Godwin Baguma, lati ilu Kijana to wa lagbegbe Kijura ni Uganda ti di awati fun ọpọlọpọ ọsẹ, eyii to sọ awọn mọlẹbi rẹ sinu iporuru.

Kí ló ṣẹlẹ̀ sí Dele Odule tó fi lọ béèrè iye tí wọ́n ń ta pósí fún ara rẹ̀? Ìdí abájọ rèé

Kí ló ṣẹlẹ̀ sí Dele Odule tó fi lọ béèrè iye tí wọ́n ń ta pósí fún ara rẹ̀? Ìdí abájọ rèé

Ọjọ́rú, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:05:24

Dele Odule sọ pe ‘‘awọn eeyan bii Olaiya Igwe mọ nipa ọrọ ti mo n sọ yii tori a jọ de ibẹ ni.’’

Àwọn ajínigbé tún jí òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ iná mọ̀nàmọ́ná IBEDC gbé, àwọn aláṣẹ ké gbàjarè síta

Àwọn ajínigbé tún jí òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ iná mọ̀nàmọ́ná IBEDC gbé, àwọn aláṣẹ ké gbàjarè síta

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:44:45

Iroyin sọ pe ẹkun ileeṣẹ mọnamọna IBEDC ni ipinlẹ Ogun lawọn oṣiṣẹ mejeeji yii ti n ṣiṣẹ ki wọn to ko sọwọ awọn afurasi ajinigbe naa.

Èmi ò sọ̀rọ̀ tàbùkù Olubadan o, ọmọ ni mo jẹ́ sí Ọba Rashidi Ladọja - Bayọ Adelabu sọ̀rọ̀ síta lẹ́yìn tí wọ́n ní ó sọ̀kò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ s’Olubadan nítorí òṣèlú

Èmi ò sọ̀rọ̀ tàbùkù Olubadan o, ọmọ ni mo jẹ́ sí Ọba Rashidi Ladọja - Bayọ Adelabu sọ̀rọ̀ síta lẹ́yìn tí wọ́n ní ó sọ̀kò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ s'Olubadan nítorí òṣèlú

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:25:09

Adelabu ni irọ to jina si otitọ ni ohun tawọn eeyan nsọ, ati pe ara ọna lati pagidina igbesẹ oṣelu oun ni.

“Ọlọ́pàá Kwara ti ọmọ mi obìnrin ọmọ ọdún 16 mọ́lé láìṣẹ̀, wọ́n ni ó gbọdọ̀ ṣẹ̀wọ̀n”

"Ọlọ́pàá Kwara ti ọmọ mi obìnrin ọmọ ọdún 16 mọ́lé láìṣẹ̀, wọ́n ni ó gbọdọ̀ ṣẹ̀wọ̀n"

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:58:58

Ninu fidio kan to n mi igboro titi loju opo X ni obinrin naa ti fẹsun kan ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara pe wọn mu ọmọ naa dipo ẹgbọn rẹ ti wọn fẹsun ole jija kan lẹyin ti ẹgbọn rẹ to jẹ afurasi na papa bora.

BBC tú àṣírí àwọn tó ń fi ajá lu jìbìtì orí ayélujára

BBC tú àṣírí àwọn tó ń fi ajá lu jìbìtì orí ayélujára

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 18:01:39

Ẹgbẹgbẹrun owo dọla lawọn eeyan ti da jọ fun itọju awọn aja lori ayelujara lai mọ pe jibiti lasan ni.

‘Mi ò lè sọ bí inú mi ṣe dùn tó,’ Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí ọmọkùnrin mẹ́ta tí Elédùà fi ta ẹbí rẹ̀ lọ́rẹ

'Mi ò lè sọ bí inú mi ṣe dùn tó,' Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí ọmọkùnrin mẹ́ta tí Elédùà fi ta ẹbí rẹ̀ lọ́rẹ

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:39:05

Lateef Adedimeji sọ loju opo Facebook rẹ wi pe ‘‘awọn eeyan ti fi ifẹ nla han si wa, o si jẹ nnkan to dara gan an.’’

Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé fítámì tó lè ṣe ara rẹ lóore wà nínú ọtí? Àlàyé rèé

Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé fítámì tó lè ṣe ara rẹ lóore wà nínú ọtí? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Àìkú, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:08:24

Fitami ọhun ti wọn n pe ni B6 ni iwadii naa sọ pe o dara fun ọpọlọ ati ẹjẹ, o si tun maa n koju aisan to ba fẹ wọ inu agọ ara.