
Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:22:54
Onoja ni ileeṣẹ Ologun ṣe iwadii wọn daadaa ti awọn si fidi rẹ mulẹ pe awọn agbebọn n fi ilu Lukupe atawọn ilu mii ni ijọba ibilẹ Shiroro, ipinlẹ Niger ṣe ibugbe ki awọn to lọ ṣekọlu si wọn.

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:06:00
Akọroyin BBC News Yoruba wa nibi iwọde naa, to si bawọn osisẹ, alasẹ ileeẹsẹ ati awọn adari ẹgbẹ osisẹ nipinlẹ Kwara sọrọ lati mọ ohun to sokunfa iwọde naa.

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:46:58
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:06:32
BBC News Yoruba kan si ọkunrin kan, Kabiru Adediran to n fi ere idaraya ìgbátí jẹun láti mọ bí eré ìdárayá náà ti gbajúmọ̀ sí àti ọ̀pọ̀ ewu tó rọ̀ mọ́ ọ.

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:51:02
FRSC ṣalaye pe ọkọ Toyota kan ti nọmba rẹ jẹ GGE722KJ gbe okiti ni ẹẹmẹta ko to di pe o jabọ lati ori afara to wa.

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:45:43
Ijọba ti gbe awon igbesẹ to laami-laaka fun atunṣe ikansira ẹni gẹgẹ bi Minisita eto ikansira ẹni ṣe sọ.

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:46:46
Eredi titipa naa bi wọn wi ni fun atunṣe, aabo ati iwadii

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:53:39
Femi Babafemi ti i ṣe Adari ikede ni NDLEA, ṣalaye ninu atẹjade naa pe baba agba ẹni ọgọta ọdun (60), torukọ rẹ n jẹ Romanus Nwabara, wa lara awọn akanda ẹda ti ọwọ ba fun ẹsun naa.

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:12:57
Minisita feto ilera Spain, Mónica Gracía sọ pe bí wọn ṣe n ko awọn eeyan bọlẹ ninu ọkọ naa lo n lọ ni mẹsọmẹsọ amọ gbogbo awọn eeyan to wa ninu ọkọ oju omi MS Hondius ni ko ṣoju pe ohunkohun n ṣe wọn.

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:11:52
Ni alẹ ọjọ Abamẹta, ọjọ Kẹsan-an, oṣu Karun-un ni ayẹyẹ naa, to jẹ ikejila iru rẹ waye ni ipinlẹ Eko nibi ti ọpọ awọn agbjumọ oṣere tiata kaakiri ilẹ Africa pejupese si.

Ọjọ́ Àìkú, 10 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:20:13
Awọn ẹsun bii kiko owo ilu si apo ara ẹni, aṣilo ipo ati igbimọ pọ huwa ọdaran ni EFCC kede pe oun n wa Sadiya Farouq fun.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 18:15:03
Ikede yii waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹsan-an oṣu Karun-un ọdun 2026, nibi ipade apapọ ẹgbẹ NDC to waye niluu Abuja.

Ọjọ́ Ajé, 11 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:51:02
FRSC ṣalaye pe ọkọ Toyota kan ti nọmba rẹ jẹ GGE722KJ gbe okiti ni ẹẹmẹta ko to di pe o jabọ lati ori afara to wa.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:58:16
Ohun to tilẹ le ni pe wọn ko le sọ pato apa ibi ti oorun naa ti n fẹ wa, bẹẹ o kari gbogbo agbegbe.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:32:07
Ṣaaju ni iroyin sọ pe ikọ ipolongo ibo Gomina Ademola Adeleke ti fẹsun kan ẹgbẹ oṣelu APC pe wọn n ran awọn janduku lati maa ba awọn atẹ ipolongo ẹgbẹ oṣelu Accord Party jẹ kaakiri ipinlẹ Osun.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:57:31
Adeleye sọ pe ọwọ tẹ awọn afurasi naa lasiko tawọn Amotekun ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ẹṣọ aabo mii latari italolobo kan ti wọn gbọ.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:33:03
Lateef Adedimeji ni aworan awọn ọmọ kan tawọn kan n gbe kaakiri ori ayelujara ti wọn n pe ni ọmọ oun kii ṣe ọmọ oun o, bi asiko ba to oun ati iyawo oun yoo fi fọto awọn ọmọ naa sita.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:58:23
Bayii ọkunrin kan ti jade, to si ti ra fọọmu lati dije tako Tinubu nibi eto idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu APC to n bọ nibi ti wọn ti maa yan awọn to gbe asia ẹgbẹ oṣelu naa nibi eto idibo gbogbogbo ọdun 2027.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 9 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:42:25
Ohun ti ọpọ awọn to ti kọwe fipo silẹ sọ ni wi pe ija to wa ninu ẹgbẹ oṣelu PDP yoo ṣe idiwo fun awọn ninu eyo idibo to n bọ.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:39:51
WHO sọ fun BBC pe ‘‘iwadii kikun si n lọ lọwọ lori awọn eeyan tawọn fura si pe wọn ni arun ọhun.’’

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 16:39:09
Ti ẹ ko ba gbagbe, adajọ yii lo ni ki agbẹjọro Sowore kunlẹ nile ẹjọ loṣu to kọja.

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:13:23
Ọbẹ ati nnkan kan to wa ninu ike kekere kan ni wọn ba lẹgbẹẹ oloogbe naa, ṣugbọn wọn ko mọ bo ya mọjele ni abi bẹẹ kọ.

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:00:29
Davido ṣalaye pe oun gbe igbesẹ yii lati ṣe ipolongo ibo fun Gomina Ademola Adeleke to fẹ dupo gomina ipinlẹ fun saa keji.

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:08:17
Egungun ti iṣẹlẹ abuku naa kan ni wọn pe orukọ rẹ ni Omebe, a gbọ pe egungun to fẹran jagidijagan ni.

Ọjọ́ Ẹtì, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:46:10
Ọga ọlọpaa ṣe ifilọlẹ naa lasiko to bawọn lọgalọga ọlọpaa ṣepade pọ niluu Abuja lana ọjọ Iṣẹgun ọjọ karun un oṣu Karun un yii.

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 18:10:35
Ninu atẹjade ti Rasheed Olawale, ẹni to jẹ agbẹnusọ fun gomina Ademola Adeleke lede lo ti fidi rẹ mulẹ pe Ọba Adeyemi Adediran, Owamiran ti iluu Esa-oke ti waja.

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 16:33:17
Wumi lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu ileeṣẹ iroyin Channels.

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:18:52
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, o to iṣẹju mẹwaa ti aigbọra ẹni ye to waye laaarin awọn mejeeji fi ṣẹlẹ, lẹyin naa si ni ipade ṣẹṣẹ bẹrẹ pada.

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:00:20
Nigba to n sọrọ ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu African A List, Tioruju ṣalaye bi o ti pada sile lati ibi to ti lọ ṣe ere ori itage, ti ko si ba iyawo rẹ ti oyun ọmọ karun un wọn wa ninu rẹ.

Ọjọ́bọ, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:49:26
Ẹka Hisbah ipinlẹ Bauchi ṣalaye pe agbegbe Azare, nijọba ibilẹ Katagum, ni ọwọ ti ba awọn baale ile meje ti wọn ni wọn n paarọ iyawo naa.

Ọjọ́rú, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 17:24:57
Eredi ifọhẹhonuhan naa ko ṣẹyin inira wọn lẹyin iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ ti kii ṣe olukọni, NASU, ninu ile ẹkọ ọhun to n lọ lọwọ.

Ọjọ́rú, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:49:14
Lọjọ Iṣẹgun lawọn aṣojuṣofin naa kede igbesẹ wọn ninu ile naa.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:52:26
Iyanṣẹlodi yii lọ n waye jakejado gbogbo faṣiti ati ile iwe gbogbo nise to jẹ ti ìjọba apapọ to ri lẹ ede yii.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 17:46:05
Ninu fidio mii to tun fi lede loju opo Facebook rẹ lọjọ Aje ọsẹ yii ni Sisi Alagbo ti kunlẹ to si n wa ẹkun mu bo ṣe n bẹbẹ fun aforiji lọwọ awọn ololufẹ rẹ, mọlẹbi rẹ atawọn ọmọ Naijiria.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:47:36
Ileeṣẹ iroyin Daily Monitor jabọ pe, Godwin Baguma, lati ilu Kijana to wa lagbegbe Kijura ni Uganda ti di awati fun ọpọlọpọ ọsẹ, eyii to sọ awọn mọlẹbi rẹ sinu iporuru.

Ọjọ́rú, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:05:24
Dele Odule sọ pe ‘‘awọn eeyan bii Olaiya Igwe mọ nipa ọrọ ti mo n sọ yii tori a jọ de ibẹ ni.’’

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:44:45
Iroyin sọ pe ẹkun ileeṣẹ mọnamọna IBEDC ni ipinlẹ Ogun lawọn oṣiṣẹ mejeeji yii ti n ṣiṣẹ ki wọn to ko sọwọ awọn afurasi ajinigbe naa.

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:25:09
Adelabu ni irọ to jina si otitọ ni ohun tawọn eeyan nsọ, ati pe ara ọna lati pagidina igbesẹ oṣelu oun ni.

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:58:58
Ninu fidio kan to n mi igboro titi loju opo X ni obinrin naa ti fẹsun kan ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara pe wọn mu ọmọ naa dipo ẹgbọn rẹ ti wọn fẹsun ole jija kan lẹyin ti ẹgbọn rẹ to jẹ afurasi na papa bora.

Ọjọ́ Ajé, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 18:01:39
Ẹgbẹgbẹrun owo dọla lawọn eeyan ti da jọ fun itọju awọn aja lori ayelujara lai mọ pe jibiti lasan ni.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:39:05
Lateef Adedimeji sọ loju opo Facebook rẹ wi pe ‘‘awọn eeyan ti fi ifẹ nla han si wa, o si jẹ nnkan to dara gan an.’’

Ọjọ́ Àìkú, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:08:24
Fitami ọhun ti wọn n pe ni B6 ni iwadii naa sọ pe o dara fun ọpọlọ ati ẹjẹ, o si tun maa n koju aisan to ba fẹ wọ inu agọ ara.