world-service-rss

BBC News Yorùbá

Kì í ṣe owó Baba Okoya nìkan ni mo ń ná - Raheem Okoya

Kì í ṣe owó Baba Okoya nìkan ni mo ń ná - Raheem Okoya

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:25:58

Okoya sọ eyi lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori bi o ṣe mu iṣẹ orin ati onkowo papọ, ti ki ọkan ko si di ọkan lọwọ.

Àwọn agbébọn tún kọlu agbègbè Kakafu àti Saare ni Kwara

Àwọn agbébọn tún kọlu agbègbè Kakafu àti Saare ni Kwara

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:28:00

Ikọlu yii waye ni agbegbe Kakafu nijọba ibilẹ Patigi, ti omiran si tun waye ni agbegbe Saare, ni ijọba ibilẹ Ifelodun.

Ọdún Ajé gbéra sọ ní Ile-Ife lónìí

Ọdún Ajé gbéra sọ ní Ile-Ife lónìí

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 06:47:54

Ọdun Aje yii maa n waye lọdọọdun ni Ile Ife nipinlẹ Osun, to si tun ti bẹrẹ lonii, ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu keji ọdun 2026.

Nàìjíríà gba ipò 36 nínú àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu ti gbilẹ̀ julọ lágbàáyé

Nàìjíríà gba ipò 36 nínú àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu ti gbilẹ̀ julọ lágbàáyé

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 11:55:13

Ipò kejìlélógóje (142) ni Nàìjíríà wà nínú àwọn orílẹ̀ èdè méjìlélọ́gọ́sàn-án (182) tí àjọ náà ṣe àgbéyẹ̀wò wọn láti mọ àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu kò wọ́pọ̀ níbẹ̀.

Ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Abuja: Mo máa ṣiṣẹ́ tako olùdíje tí kò bá ṣe tí Ààrẹ Bola Tinubu - Wike

Ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Abuja: Mo máa ṣiṣẹ́ tako olùdíje tí kò bá ṣe tí Ààrẹ Bola Tinubu - Wike

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 15:28:36

Wike sọ ọrọ yii niluu Abuja lasiko ọjọbi Sẹbetọ Sandy Onor, to pe ọgọta ọdun laye.

Ìjọba àpapọ̀ kọminú lórí bí àwọn ọmọ Naijiria ṣe ń lọ jagun nílẹ̀ òkèrè láì mọ̀

Ìjọba àpapọ̀ kọminú lórí bí àwọn ọmọ Naijiria ṣe ń lọ jagun nílẹ̀ òkèrè láì mọ̀

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:04:37

Ninu atẹjade kan lọjọ Aiku, agbẹnusọ ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ilẹ okere, Kimiebi Imomotimi Ebienfa, sọ pe awọn ilẹ okere kan n tan ọmọ Naijiria ẹ lati mu ki wọn lọ jagun nilẹ okeere laimọ.

Israel rọ òjò àdó olóró lé Gaza lórí, èèyàn mọ́kànlá jáde láyé

Israel rọ òjò àdó olóró lé Gaza lórí, èèyàn mọ́kànlá jáde láyé

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:54:46

Ileeṣẹ ọmọ ogun Israel loun ju awọn ado oloro naa lẹyin ti awọn ọmọ ogun Hamas yẹ adehun jogun-o-mi to wa laarin wọn.

Agbésùnmọ̀mí kọlu ìlú mẹ́ta ní Niger, ṣekúpa èèyàn 30, dáná sun ilé àti àgọ́ ọlọ́pàá

Agbésùnmọ̀mí kọlu ìlú mẹ́ta ní Niger, ṣekúpa èèyàn 30, dáná sun ilé àti àgọ́ ọlọ́pàá

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:09:57

A gbọ pe oniruru ohun ija oloro lawọn agbebọn naa ko lọwọ, bi wọn ṣe yinbọn pa awọn kan naa ni wọn fi ọbẹ rẹ ọrun awọn mii ti wọn si sọ ina si ọpọlọpọ ile ninu ikọlu ọhun.

Agbébọn ṣàfihàn fídíò ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn tí wọ́n jí gbé ní Kwara, wọ́n ní 176 làwọn jí gbé, kìí ṣe 32

Agbébọn ṣàfihàn fídíò ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn tí wọ́n jí gbé ní Kwara, wọ́n ní 176 làwọn jí gbé, kìí ṣe 32

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 07:37:02

Ọjọ kẹta osu Keji, ọdun 2026 yii ni awọn agbebọn ṣakọlu si ilu Woro ni ijọba ibilẹ Kaiama ni ipinlẹ Kwara ti wọn si pa ọgọọrọ eeyan, wọn si tun gbe aimọye awọn obinrin ati awọn ọmọde gbe lọ.

Wo orílẹ́èdè mẹ́sàn án tí ìjọba ti fòfin de tàbí tí ó ti nira láti ṣe àyájọ́ ọjọ́ olólùfẹ́

Wo orílẹ́èdè mẹ́sàn án tí ìjọba ti fòfin de tàbí tí ó ti nira láti ṣe àyájọ́ ọjọ́ olólùfẹ́

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 18:22:46

Ayajọ naa bẹrẹ pẹlu awọn ọmọlẹyin Kristi nigba ti wọn maa n ranti agbaọjẹ kan ninu igbagbọ ti wọn n pe orukọ rẹ St. Valentine ẹni ti wọn gbagbọ wi pe o fi ifẹ han sawọn eeyan.

Atiku, Bashir Ahmad korò ojú sí oṣù Kejì ọdún 2027 tí INEC kéde fún ìbò ààrẹ torí Ramadan, INEC ṣàlàyé ìdí abájọ

Atiku, Bashir Ahmad korò ojú sí oṣù Kejì ọdún 2027 tí INEC kéde fún ìbò ààrẹ torí Ramadan, INEC ṣàlàyé ìdí abájọ

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 15:09:30

INEC ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita eyi ti ọkan lara awọn ọga agba ajọ naa, Muhammed Kudu Haruna, buwọlu wi pe asiko to wa ninu iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999 ni awọn fi ṣe agbekalẹ ọjọ idibo ọhun.

“Awuyewuye lórí aṣọ tó bo Kaaba, tó jẹ́ ohun mánigbàgbé tí wọ́n fi ránṣẹ́ sí Epstein’’

"Awuyewuye lórí aṣọ tó bo Kaaba, tó jẹ́ ohun mánigbàgbé tí wọ́n fi ránṣẹ́ sí Epstein''

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:41:41

Aṣọ yii ni wọn fi siliki dudu ṣe, Kiswa jẹ aṣọ to ni awọn akọle Al-Qur’an lara ti wọn kọ pẹlu wura ati fadaka. O bo gbogbo awọn odi ode mẹrin ti Kaaba, eto okuta ni aarin Mossalassi nla ni Mekka.

Àwọn agbésùnmọ̀mí kọ lẹ́tà sí ìlú mẹ̀ta ní Kwara pé àwọn ń bọ̀

Àwọn agbésùnmọ̀mí kọ lẹ́tà sí ìlú mẹ̀ta ní Kwara pé àwọn ń bọ̀

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:31:22

Awọn ilu mẹta ti wọn kọ iwe ọhun si ni ilu Ira, Inaja ati Hahọ.

Seyi Makinde sọ Baálẹ̀ mẹ́rìnlá di ọba aládé l’Oyo

Seyi Makinde sọ Baálẹ̀ mẹ́rìnlá di ọba aládé l'Oyo

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 19:28:27

Igbakeji gomina Oyo, Bayo Lawal to soju fún Makinde lo gbe ọ̀pá àṣẹ fún àwọn baalẹ tó di ọba náà.

Agbébọn ń bèèrè N40m owó ìtúsílẹ̀ fún ìyàwó asọ́gbó tí wọ́n jígbé lẹ́yìn tí wọ́n pa ọkọ rẹ̀ ní Kwara

Agbébọn ń bèèrè N40m owó ìtúsílẹ̀ fún ìyàwó asọ́gbó tí wọ́n jígbé lẹ́yìn tí wọ́n pa ọkọ rẹ̀ ní Kwara

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 15:01:02

Tẹ o ba gbagbe, irọlẹ Ọjọru, ọjọ kọkanla osu Keji ọdun 2026 yii ni awọn agbebọn ya wọ ilu Oba Isin, nijoba ibilẹ Isin, ti wọn si ko araalu sinu ipayinkeke.

INEC kéde ọjọ́ ìbò ààrẹ 2027 àtàwọn mí-ín

INEC kéde ọjọ́ ìbò ààrẹ 2027 àtàwọn mí-ín

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 14:16:33

Alaga ajọ INEC, Ọjọgbọn Joash Amupitan lo fi alakalẹ eto idibo naa lede lọjọ Ẹti, ọjọ kẹtala, oṣu Keji ọdun 2026, nibi ipade oniroyin kan l’Abuja.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ṣọ́ọ̀ṣì tó bá ṣe ìsìn kọ́ja aago mẹ́rin ìrọ̀lẹ́ yóò fojú winá òfin- ìjọba Kogi kìlọ̀ nítorí ìkọlù agbébọn

Ṣọ́ọ̀ṣì tó bá ṣe ìsìn kọ́ja aago mẹ́rin ìrọ̀lẹ́ yóò fojú winá òfin- ìjọba Kogi kìlọ̀ nítorí ìkọlù agbébọn

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:44:22

Gẹgẹ bi Kọmiṣanna eto iroyin ni Kogi, Kingsley Femi Fanwo, ṣe wi, ikilọ yii n waye lati dena ikọlu awon agbebọn fun awon olujọsin lasiko ti wọn ba n ṣe isin to pẹ ju lọwọ.

Ilé ẹjọ́ nỉ Eko sọ ọmọ ilẹ̀ China méjì sẹ́wọ̀n fún jìbìtì orí ayélujára

Ilé ẹjọ́ nỉ Eko sọ ọmọ ilẹ̀ China méjì sẹ́wọ̀n fún jìbìtì orí ayélujára

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 06:02:36

Ilé ẹjọ́ ní tàbí káwọn èèyàn náà san owó ìtanràn mílíọ̀nù márùndínlọ́gọ́ta náírà.

Ajara wà láàrin wa báyìí, O ń wo ǹkan tí à ń ṣe…..Alfa Ibrahim to rọ́ wáàsí

Ajara wà láàrin wa báyìí, O ń wo ǹkan tí à ń ṣe.....Alfa Ibrahim to rọ́ wáàsí

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:01:39

Oṣere ti ọpọ eeyan mọ si Anti Ajara naa jade laye lọjọ karun-un oṣu Keji ọdun 2026 yii, lẹyin aisan to ni I ṣe pẹlu ẹdọ, to si tun wa nipo iloyun lasiko ti ọlọjọ de naa.

Ìdí tí mo fi takú pé mi ò ní í tẹ̀le àwọn agbófinró tó fẹ́ mú mi rèé - El-Rufai

Ìdí tí mo fi takú pé mi ò ní í tẹ̀le àwọn agbófinró tó fẹ́ mú mi rèé - El-Rufai

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:06:05

Bi iroyin naa ṣe gbode ni ọpọ eeyan n beere ohun to ṣẹlẹ ti wọn yoo fi mu El-Rufai, ko si pẹ ti El-Rufai funra ẹ fi fidi ẹ mulẹ nipasẹ Olugbani-nimọran lori iroyin rẹ, Muyiwa Adekeye.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 13:02:59

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Kenya fòfin de fífi owó ṣe òdòdó

Kenya fòfin de fífi owó ṣe òdòdó

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:01:18

Láti fi owó ṣe òdòdó, wọ́n máa ká owó, tí wọ́n sì máa to àwọn owó náà papọ̀ dáadáa láti lè jẹ́ kó dàbí òdòdó.

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìpàdé ìdákọ́nkọ́ tí Makinde ṣe pẹ̀lú Atiku àti Babangida

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìpàdé ìdákọ́nkọ́ tí Makinde ṣe pẹ̀lú Atiku àti Babangida

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:13:47

Ọpọ eeyan lo ti n beere wi pe ki ni ipade Makinde to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP ati Atiku ti i ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣelu ADC pẹlu Babangida le da le lori.

Ohun tí a mọ̀ nípa àfikún ọmọ ogun 200 t’America fẹ́ẹ́ fi ránṣẹ́ sí Naijiria

Ohun tí a mọ̀ nípa àfikún ọmọ ogun 200 t'America fẹ́ẹ́ fi ránṣẹ́ sí Naijiria

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 16:36:21

Tẹ o ba gbagbe, ṣaaju ni ikede kan ti waye lati America, pe oun yoo fi ọmọ ogun ranṣẹ silẹ yii, ti Ọgagun Samuel Uba, agbẹnusọ ileeṣẹ aabo ni Naijiria si fidi ẹ mulẹ fun BBC.

Èèyàn 80 móríbọ́ lọ́wọ́ ikú bí bààlúù tó ń lọ sí Port Harcourt ṣe balẹ̀ sí Benin

Èèyàn 80 móríbọ́ lọ́wọ́ ikú bí bààlúù tó ń lọ sí Port Harcourt ṣe balẹ̀ sí Benin

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 18:02:06

Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ilu Eko ni ọkọ baaluu Arik Air Boeing 737-700 naa ti gbera, ṣugbọn ko le de Port Harcourt to n lọ to fi koju iṣoro laaarin ọna.

APC, NNPP Kọminú lórí ìgbésẹ̀ Amẹ́ríkà láti fòfin de Kwankwaso lórí ìkọlù sáwọn Kristẹni

APC, NNPP Kọminú lórí ìgbésẹ̀ Amẹ́ríkà láti fòfin de Kwankwaso lórí ìkọlù sáwọn Kristẹni

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:40:06

Ní ọjọ́ Kẹwàá, oṣù Kejì, ọdún 2026 ni aṣòfin ilẹ̀ Amẹ́ríkà, Riley Moore kéde lójú òpó X rẹ̀ pé òun àtàwọn akẹgbẹ́ òun, Chris Smith, Brian Mast àti Bill Huizenga ti gbé àbá kan dìde láti kojú bí wọ́n ṣe ń pa àwọn ọmọlẹ́yìn Kristi ní Nàìjíríà.

Wo ohun mẹ́fà tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ismail Abba Yusuf alága àjọ Hajj tuntun tí Tinubu yàn

Wo ohun mẹ́fà tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ismail Abba Yusuf alága àjọ Hajj tuntun tí Tinubu yàn

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:38:18

Ọpọ iroyin lo jade lọjọ Aje pe Usman kọwe fipo rẹ silẹ nitori ọpọ ẹsun ti wọn fi kan.

Ọwọ́ ọlọ́pàá Kwara tẹ afurasí ajínigbé tó múra bíi oníbárà

Ọwọ́ ọlọ́pàá Kwara tẹ afurasí ajínigbé tó múra bíi oníbárà

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:36:51

Ni ọjọ Kejila, oṣu Keji ọdun 2026 ni iroyin gba ori ayelujara kan wi pe awọn ọlọpaa Kwara nawọ gan afurasi kan to n ṣe bii onibara.

Ẹ̀yin Gómìnà, ẹ ṣètò láti pèsè iṣẹ́, ètò ìlera alábọ́dé àti ohun amáyédẹrùn fún aráàlú - Tinubu

Ẹ̀yin Gómìnà, ẹ ṣètò láti pèsè iṣẹ́, ètò ìlera alábọ́dé àti ohun amáyédẹrùn fún aráàlú - Tinubu

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:24:09

Tinubu ni oun naa ti n gbe awọn igbesẹ akin lori ọrọ aje eyi ti yoo jẹ ki araalu gbaye gbadun.

Nàìjíríà gba ipò 36 nínú àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu ti gbilẹ̀ julọ lágbàáyé

Nàìjíríà gba ipò 36 nínú àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu ti gbilẹ̀ julọ lágbàáyé

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 11:55:13

Ipò kejìlélógóje (142) ni Nàìjíríà wà nínú àwọn orílẹ̀ èdè méjìlélọ́gọ́sàn-án (182) tí àjọ náà ṣe àgbéyẹ̀wò wọn láti mọ àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu kò wọ́pọ̀ níbẹ̀.

Ọkúnrin tó sọ ara rẹ̀ di obìnrin ni afurasí tó pa èèyàn mẹ́sàn-án ní Canada -Ọlọ́pàá kéde

Ọkúnrin tó sọ ara rẹ̀ di obìnrin ni afurasí tó pa èèyàn mẹ́sàn-án ní Canada -Ọlọ́pàá kéde

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 14:49:52

Ninu alaye ọlọpaa nipa afurasi yii ni wọn ti sọ pe ìbí ọkunrin ni wọn bi i, amọ Van Rootselaar maa n pe ara rẹ ni obinrin.

Báǹkì àgbà Naijiria ṣòfin ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fà fún ẹni tó bá fi owó ṣe òdòdó ìfẹ́

Báǹkì àgbà Naijiria ṣòfin ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fà fún ẹni tó bá fi owó ṣe òdòdó ìfẹ́

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 13:44:29

Iroyin to gba ori ayelujara l’Ọjọbọ naa ṣalaye, pe ijiya to wa fun awọn to ba tabuku owo naira nipa nina a loju agbo, naa lo wa fun ẹni to ba n fi owo ṣe ododo ifẹ lati fi tọrẹ fun ololufẹ rẹ.

Àwọn ajínigbé yọ̀nda àwọn mẹ́rin tí wọ́n jígbé ní Kwara

Àwọn ajínigbé yọ̀nda àwọn mẹ́rin tí wọ́n jígbé ní Kwara

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 13:31:24

Ọkan lara awọn mọlẹbi awọn ti wọn ji gbe ọgbẹni Yinka Ọmọniyi sọ fun BBC News Yoruba pe lootọ ni wọn ti yọnda awọn mẹrin naa, ti wọn si ti darapọ mọ awọn ẹbi wọn.

Àwọn ajínigbé tó jí dókítà gbé l’Edo ṣìrìn, wọ́n fi ẹsẹ̀ ara wọn rìn wọnú àhámọ́ òfin

Àwọn ajínigbé tó jí dókítà gbé l'Edo ṣìrìn, wọ́n fi ẹsẹ̀ ara wọn rìn wọnú àhámọ́ òfin

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:09:33

Tẹ o ba gbagbe, oṣu to kọja yii ni iroyin gbode, pe awọn ajinigbe ji Dokita kan, Abu Babatunde, gbe ni Auchi, ipinlẹ Edo .

Ìdí ti ayẹyẹ ọjọ́ ìbí mi fi wáyé bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọjọ́ náà ni ìyá mi jáde láyé rèé- Fathia Williams

Ìdí ti ayẹyẹ ọjọ́ ìbí mi fi wáyé bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọjọ́ náà ni ìyá mi jáde láyé rèé- Fathia Williams

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:54:23

Williams kede eyi lẹyin wakati diẹ ti o ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi, ọdun marindinlọgọta niluu Eko.

Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera JOHESU padà sẹ́nu iṣẹ́ lẹ́yìn tí wọ́n ti gúnlè ìyanṣẹ́lódì fún bíi oṣù mẹ́ta

Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera JOHESU padà sẹ́nu iṣẹ́ lẹ́yìn tí wọ́n ti gúnlè ìyanṣẹ́lódì fún bíi oṣù mẹ́ta

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Èrèlè 2026 ní 14:35:41

Ẹgbẹ oṣiṣẹ JOHESU pinnu lati pada sẹnu isẹ nibi ipade igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ naa to waye niluu Abuja lọjọ Ẹti ọsẹ to kọja.

Èèwọ̀ ni fún ẹnikẹ́ni láti daran jẹko ní ìta gbangba nílẹ̀ Ibadan - Olubadan

Èèwọ̀ ni fún ẹnikẹ́ni láti daran jẹko ní ìta gbangba nílẹ̀ Ibadan - Olubadan

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 10 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:05:34

Olubadan ṣèkìlọ̀ fáwọn darandaran káàkiri ìpínlẹ̀ náà láti jáwọ́ nínú dída ẹran jẹko ní ìta gbangba tí wọn kò bá fẹ́ kojú ìgbẹ́jọ́ ilé ẹjọ́.