world-service-rss

BBC News Yorùbá

'’Èyi ni ipa tí Bàba-bàbá mi kó nínú ogun abẹ́lé Biafra’‘-Meji Alabi, gbajúmọ̀ adarí orin

''Èyi ni ipa tí Bàba-bàbá mi kó nínú ogun abẹ́lé Biafra''-Meji Alabi, gbajúmọ̀ adarí orin

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Òkúdu 2026 ní 08:05:39

Agbekalẹ BBC Africa lori ogun abẹle Biafra, to ni i ṣe pẹlu gbajumọ adari orin lagbaaye, Meji Alabi

Ẹgbẹ́ olùkọ́ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì l’Oyo lórí àwọn tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso, Tinubu kéde ìgbésẹ láti gba aṣógbó 1,000 síṣẹ́

Ẹgbẹ́ olùkọ́ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì l'Oyo lórí àwọn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, Tinubu kéde ìgbésẹ láti gba aṣógbó 1,000 síṣẹ́

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Òkúdu 2026 ní 09:39:40

Ṣaaju ni ẹgbẹ NUT ti sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo wi pe ki wọn ṣe ifẹhonuhan lati beere fun itusilẹ awọn tawọn janduku agbebọn ji gbe.

Ìfẹ̀hónúhàn bẹ́ sílẹ̀ ní France lẹ́yìn tí PSG gba ife ẹ̀yẹ Champions League, èèyàn 219 farapa

Ìfẹ̀hónúhàn bẹ́ sílẹ̀ ní France lẹ́yìn tí PSG gba ife ẹ̀yẹ Champions League, èèyàn 219 farapa

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:27:18

A gbọ pe eeyan mẹjọ lo wa ni ẹsẹ kan aye ẹsẹ kan ọrun gẹgẹ bii ọrọ minisita fun ọrọ abẹle, Laurent Nuñez.

Makinde ṣàbẹ̀wò sẹ́bí àwọn èèyàn tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso, ọkọ Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n gbé bú sẹ́kún

Makinde ṣàbẹ̀wò sẹ́bí àwọn èèyàn tí wọ́n jí gbé  l'Ogbomoso, ọkọ Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n gbé bú sẹ́kún

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:07:55

Makinde sọ fún gbogbo eeyan to wa nibi ipade naa to waye ni Esinele pe kí wọn ma foya torí ìjọba n ṣiṣẹ takun takun lati ri pe won doola awon t’awọn jàndùkú agbébọn ji gbe lọ.

Agbébọn jí ajagunfẹ̀yìntì àti ìyàwọ rẹ̀ gbé ní Katsina

Agbébọn jí ajagunfẹ̀yìntì àti ìyàwọ rẹ̀  gbé ní Katsina

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:27:37

Ọgagun Rabe Abubakar to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun Naijiriala larin ọdun 2015 si ọdun 2017 ni wọn ji gbe lasiko ti wọn kọlu ọkọ rẹ lasiko to n rinrinajo lọ si ipinlẹ Katsina.

'’Tí ìjọba bá lè gba ọmọ Yoruba láyè láti lo ìlànà ti ìbílẹ̀, ilẹ̀ wa yóò bọ́ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀mí’’

''Tí ìjọba bá lè gba ọmọ Yoruba láyè láti lo ìlànà ti ìbílẹ̀, ilẹ̀ wa yóò bọ́ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀mí''

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:44:54

Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, Obarisa Ilorin Afonja, Oba Omobolaji Adifakawo Agbomola, sọ pe awọn agbara ti Afọnja fi jagun si wa sibẹ, awọn si le lo o lati sẹgun ijinigbe ati ipaniyan ti ijọba ba gba awọn laye.

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́jọ lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dáná sun ilé ẹkọ̀ tí akẹgbẹ́ wọn 16 ti kú

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́jọ lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dáná sun ilé ẹkọ̀ tí akẹgbẹ́ wọn 16 ti kú

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:17:04

Lẹyin ti agbofinro fi ọrọ wa awọn olukọ ati ọpọ akẹkọọ lẹnuwo, ti wọn si wo ẹrọ CCTV to wa nibẹ ni wọn fidi rẹ mulẹ pe akẹkọọ mẹjọ kan lo pilẹ iṣẹlẹ naa ti wọn si sọ ina sile ẹkọ ọhun.

Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti máa san ₦100,000 gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ

Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti máa san ₦100,000 gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ

Ọjọ́ Àìkú, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:42:38

Wọn ni eyii jẹ ọkan lara awọn ọna lati mu aye dẹrun fun awọn oṣiṣẹ naa latari bi ọrọ aje Naijiria ṣe le koko lonii.

Seyi Makinde ni yóò ṣojú wa nínú ètò ìdìbò Ààrẹ ọdún 2027 – Ẹgbẹ́ òṣèlú APM

Seyi Makinde ni yóò ṣojú wa nínú ètò ìdìbò Ààrẹ ọdún 2027 – Ẹgbẹ́ òṣèlú APM

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:59:02

‎Ikede yii lo waye nibi eto idibo abẹlẹ ẹgbẹ oṣelu naa to waye ninu gbangan ọmọwe agba Theofilus Ogunlesi to wa ni adojuko ile iwosan UCH, nilu uIbadan.

Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé

Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 19:40:03

Awọn mọlẹbi oloogbe naa lo kede iroyin iku rẹ ninu atẹjade kan lọjọ Abamẹta.

Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin Ghana buwọ́lu òfin tó kéde ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún ìbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo

Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin Ghana buwọ́lu òfin tó kéde ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún ìbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 15:03:30

Ofin tuntun ọhun tun ke pe araalu lati fi to ijọba leti ti wọn ba kofiri ẹnikẹni to ba n ṣe nnkan naa ti wọn ti fofin de.

Báwo ni ayẹyẹ Ojude Oba 2026 ṣe rí láì sí Awujale Ijebu lórí oyè? Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ rèé

Báwo ni ayẹyẹ Ojude Oba 2026 ṣe rí láì sí Awujale Ijebu lórí oyè? Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ rèé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 12:20:02

Ṣaaju eto ayeye ọdun ọhun to waye lọjọ Ẹti, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Karun-un ti a wa yii, ni oniruuru awuyewuye ti n waye lori boya eto naa ko ni waye lọdun yii.

‘A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso,’ àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l’Oyo

'A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso,' àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l'Oyo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:34:49

‎Awọn olukọ naa bẹrẹ iwọde wọn lati agbegbe Iwo road niluu Ibadan ti wọn si gba Idi-ape, Gate titi de ọfiisi ijọba Ipinlẹ Oyo ni Agodi niluu ibadan.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:56:41

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Taa ni Balogun Kuku, bàbá olówó tó mú ẹ̀sìn Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, tó tún bẹ̀rẹ̀ ọdún Ojude Ọba?

Taa ni Balogun Kuku, bàbá olówó tó mú ẹ̀sìn Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, tó tún bẹ̀rẹ̀ ọdún Ojude Ọba?

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:53:19

Itan igbe aye Balogun Bello Kuku, ẹni to mu Islam wọ ilẹ Ijẹbu, to si tun bẹrẹ ayẹyẹ ọdun Ojude Oba to di gbaju-gbaja ni Ijebu Ode.

Kí ni pàtàkì Òkúta Dúdú táwọn olùjọsìn máa ń fọwọ́ kan tàbí fẹnu kò ní Kaaba lásìkò Hajj?

Kí ni pàtàkì Òkúta Dúdú táwọn olùjọsìn máa ń fọwọ́ kan tàbí fẹnu kò ní Kaaba lásìkò Hajj?

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:53:09

Lọdọọdun ni ọpọ eeyan maa n ti ara wọn, koda wọn maa n tẹ awọn mii mọlẹ nibẹ lati ri pe awọn lanfaani lati fọwọ kan okuta naa.

Àlàyé rèé lórí bí fọ́nrán ohùn Tinubu tí wọ́n fi AI ṣe, ṣe dá wàhálà sí VDM lọ́rùn, tí wọn ṣí ló gbọdọ̀ fojú winá òfin

Àlàyé rèé lórí bí fọ́nrán ohùn Tinubu tí wọ́n fi AI ṣe, ṣe dá wàhálà sí VDM lọ́rùn, tí wọn ṣí ló gbọdọ̀ fojú winá òfin

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:26:49

Bi AI ṣe wulo lati mu iṣẹ ya kankan, bẹẹ naa ni awọn to mọ lilo rẹ nidakeji tun maa n lo o lati ya fidio eeyan tabi lo ohùn ẹnu ẹni ti wọn ba fẹ fi ṣe jamba fun.

Ìtàn mánigbàgbé: Bí ilà kíkọ ṣe bẹ̀rẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun

Ìtàn mánigbàgbé: Bí ilà kíkọ ṣe bẹ̀rẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:19:43

BBC News Yorùbá ṣe wọ inú ìtàn lọ, láti ṣe ilanilọyẹ lórí ohun tó fà á, tí ìran Yoruba ṣe ń kọ ila àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun.

Aṣọ oníbúrẹ́dì 500 tí mo wọ lọ síbi àmì ẹ̀yẹ AMVCA dá egbò sí mi lẹ́yìn, mú ẹ̀yìn ro mi, ó jẹ́ kí n fara ṣèṣe - Queen Mercy

Aṣọ oníbúrẹ́dì 500 tí mo wọ lọ síbi àmì ẹ̀yẹ AMVCA dá egbò sí mi lẹ́yìn, mú ẹ̀yìn ro mi, ó jẹ́ kí n fara ṣèṣe - Queen Mercy

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:56:49

Nigba to n sọrọ, Mercy ni oun kọ loun ran aṣọ naa, bi ko ṣe gbajumọ aranṣọ Toyin Lawani to jẹ ọga ileeṣẹ Tianah Empire.

Iran ṣàlàyé ìdí abájọ tó fi ṣèkọlù sí ibùdó ológun Amẹrika

Iran ṣàlàyé ìdí abájọ tó fi ṣèkọlù sí ibùdó ológun Amẹrika

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:15:58

Ajọ IRGC ni oun ṣekọlu si ibudo naa lẹyin ti Amẹrika yin ado oloro si ẹkun guusu Iran.

Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí

Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:52:55

Ninu ọsẹ yii naa ni ọrọ fọnran ohun ti wọn fi AI gbe jade bọ sori ayelujara, nibi ti wọn ti fi ohùn ẹnu Tinubu sọ awọn ọrọ to n tako araalu, to si le da rugudu silẹ.

Wo kókó ohun mọ́kànlá tí Tinubu fi ránṣẹ́ sọ́mọ Náíjíríà lórí ààbò àti ọrọ̀ ajé láti sàmì ọdún kẹta rẹ̀ nípò ààrẹ

Wo kókó ohun mọ́kànlá tí Tinubu fi ránṣẹ́ sọ́mọ Náíjíríà lórí ààbò àti ọrọ̀ ajé láti sàmì ọdún kẹta rẹ̀ nípò ààrẹ

Ọjọ́ Ẹtì, 29 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 14:32:10

Aarẹ Bola Tinubu ni yiyọ owo iranwọ ori epo, riro owo naira lagbara lọja agbaye ati gbigbe ogun ti aabo to mẹhẹ ti oun dawọle, ti so eso rere.

“Ẹ jọ̀ọ́ ẹ má jẹ́ kí wọ́n fi ẹ̀mí wa ṣòfò,” àwọn olùkọ́ tí agbésùnmọ̀mí jígbé l’Ogbomoso rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba

"Ẹ jọ̀ọ́ ẹ má jẹ́ kí wọ́n fi ẹ̀mí wa ṣòfò," àwọn olùkọ́ tí agbésùnmọ̀mí jígbé l'Ogbomoso rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:01:28

Ọga ile ẹkọ to sọrọ ninu fidio tawọn ajinigbe fi sori ayelujara ni ‘‘a wa ninu otutu, a wa ninu ojo ati ninu oorun, awa atawọn ọmọ kekere ni a wa nibi. Ẹ jọwọ, a n bẹ yin.”

Ọlọ́pàá méjì kú ní ìpínlẹ̀ Osun lẹ́yìn tí ọkọ̀ gbá wọn lójú pópó

Ọlọ́pàá méjì kú ní ìpínlẹ̀ Osun lẹ́yìn tí ọkọ̀ gbá wọn lójú pópó

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:40:56

Ọlọpaa orukọ awọn ọlọpaa meji ti ọrọ naa kan lede gẹgẹ bii Kehinde ati Tobi lai mẹnuba orukọ wọn keji.

Ìrọ́ ni pé PDP dara pọ̀ mọ́ APM l‘Oyo, ẹgbẹ́ wa tóbi ju ká dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú kankan lọ, àwa lá borí ìbò ààrẹ - Gbolarumi

Ìrọ́ ni pé PDP dara pọ̀ mọ́ APM l‘Oyo, ẹgbẹ́ wa tóbi ju ká dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú kankan lọ, àwa lá borí ìbò ààrẹ - Gbolarumi

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:06:51

BBC News Yoruba ba Amofin Azeem Gbolarumi sọrọ ni kete to wọle ibo abẹle PDP bii oludije gomina fẹgbẹ PDP nipinlẹ Oyo.

Arafat Day: Wo ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam

Arafat Day: Wo ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:46:23

Ọjọ Arafa ni ọjọ kẹsan oṣu Zul-Hijjah, ni onka oṣù ojú ọrun, tii se ọjọ Arafa.

Ìjà abẹnú ADC fẹjú síi, igun kan kẹ̀yìn sí David Mark, yan Dumebi Kachikwu bíi olùdíje ààrẹ, bí igun Mark ṣe fẹ́ yan olùdíje aarẹ lónìí

Ìjà abẹnú ADC fẹjú síi, igun kan kẹ̀yìn  sí David Mark, yan Dumebi Kachikwu bíi olùdíje ààrẹ, bí igun Mark ṣe fẹ́ yan olùdíje aarẹ lónìí

Ọjọ́ Ajé, 25 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 09:03:04

Ana ode yiii ti I ṣe ọjọ Aiku, ọjọ kẹrinlelogun oṣu Karun-un ọdun 2026, ni igun tuntun yi tu igbimọ amuṣẹṣe ‘National working committee’ (NWC) ti David Mark n dari ka, ti wọn si yan Dumebi Kachikwu lẹyẹ o-sọka.

“Ọ̀rọ̀ aláàgànná àti ọlọ́tí ni pé Oluwo wú òkú àwọn ọba tí wọ́n sín sí ààfin rẹ̀, ṣe ló tún ibòji wọn ṣe”

"Ọ̀rọ̀ aláàgànná àti ọlọ́tí ni pé Oluwo wú òkú àwọn ọba tí wọ́n sín sí ààfin rẹ̀, ṣe ló tún ibòji wọn ṣe"

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:33:23

Awọn eeyan to sunmọ ọba Akanbi, ti wọn si mọ awọn ohun to ṣẹlẹ nipa awọn oju oori yii ti n ṣe alaye tiwọn.

Àjọ NEMA kéde agbègbè 37 tó wà nínú ewu ẹ̀kún omi, 15 l’Eko, 19 l’Ogun, 3 ní Nassarawa

Àjọ NEMA kéde agbègbè 37 tó wà nínú ewu ẹ̀kún omi, 15 l'Eko, 19 l’Ogun, 3 ní Nassarawa

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 11:03:47

NEMA ni kawọn to ba n gbe ni bebe okun lagbegbe naa tete fi ibẹ silẹ

Ta ló wọlé ìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord láti dupò Gómìnà l’Oyo láàrin Oriyomi àti Gudugudu? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ta ló wọlé ìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord láti dupò Gómìnà l'Oyo láàrin Oriyomi àti Gudugudu? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 08:26:10

Ṣaaju eto idibo naa ni ọkan lara awọn oludije ninu mẹta sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu Accord, Fatai Owoseni, juwọ silẹ pe oun ko dije mọ.

Tinubu wọlé ìbò abẹ́nú APC láti díje fún ipò ààrẹ lẹ́ẹ̀kejì, iye ìbò tó rí rèé

Tinubu wọlé ìbò abẹ́nú APC láti díje fún ipò ààrẹ lẹ́ẹ̀kejì, iye ìbò tó rí rèé

Ọjọ́ Àìkú, 24 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 17:03:20

Sẹnẹtọ Pius Anyim lo kede esi ibo naa lonii ọjọ Aiku ọjọ kẹrinlelogun oṣu Karun un yii.

Afurasí tó fẹ́ kó àwọn ọmọdé lọ ṣiṣẹ́ aṣẹ́wó ní Ghana rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he l’Ogun

Afurasí tó fẹ́ kó àwọn ọmọdé lọ ṣiṣẹ́ aṣẹ́wó ní Ghana rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he l'Ogun

Ọjọ́ Àìkú, 24 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 10:27:13

Awọn ọmọde naa bi kootu ṣe darukọ wọn ni Bright Edim, ọmọ ọdun mẹẹẹdogun ati Mary Ekong toun naa jẹ ọmọ ọdun mẹẹẹdogun (15) bakan naa.

AI lè gba iṣẹ́ lọ́wọ́ àwọn èèyàn tí kò bá fi kún ìmọ̀ ẹ̀rọ wọn lẹ́nu iṣẹ́ ọba-Ìjọba àpapọ̀

AI lè gba iṣẹ́ lọ́wọ́ àwọn èèyàn tí kò bá fi kún ìmọ̀ ẹ̀rọ wọn lẹ́nu iṣẹ́ ọba-Ìjọba àpapọ̀

Ọjọ́ Àìkú, 24 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 07:11:50

Bo tilẹ jẹ pe ijọba tun fi awọn oṣiṣẹ lọkan balẹ pe lilo AI ko tumọ si pe yoo rọpo awọn eeyan patapata, sibẹ, o ṣee ṣe kawọn kan padanu iṣẹ wọn.

Ta ló yẹ kó pa ẹran Ileya, ṣé ẹ̀ṣẹ̀ wà fún ẹni tí kò bá pa ẹran, kí ni ẹni tó bá fẹ́ pa ẹran gbọdọ̀ ṣe?

Ta ló yẹ kó pa ẹran Ileya, ṣé ẹ̀ṣẹ̀ wà fún ẹni tí kò bá pa ẹran, kí ni ẹni tó bá fẹ́ pa ẹran gbọdọ̀ ṣe?

Ọjọ́rú, 27 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:58:10

Ileya jẹ́ ọdún tó ṣe pàtàkì sáwọn Mùsùlùmí nítorí òhun ni wọ́n kà kún ọdún ńlá níbi tí wọ́n ti máa ń pa ẹran àgbò.

Olóòtú Ìjọba Senegal Sonko di adarí ilé aṣòfin lẹ́yìn tí Ààrẹ Faye yọ ọ́ nípò

Olóòtú Ìjọba Senegal Sonko di adarí ilé aṣòfin lẹ́yìn tí Ààrẹ Faye yọ ọ́ nípò

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 16:58:17

O ti to oṣu meloo kan bayii ti faakaja ti n waye laarin Aarẹ Faye ati Olootu ijọba Sonko.

Ọlọ́pàá àtàwọn ọdẹ ṣekúpa afurasí ajínigbé mẹ́ta, dóòlà èèyàn tí wọ́n jí gbé lágbègbè Oke Ogun l’Oyo

Ọlọ́pàá àtàwọn ọdẹ ṣekúpa afurasí ajínigbé mẹ́ta, dóòlà èèyàn tí wọ́n jí gbé lágbègbè Oke Ogun l'Oyo

Ọjọ́bọ, 28 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 06:30:32

Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, DSP Ayanlade Ọlayinka, lo fìdí ọrọ yìí múlẹ nínú atẹjade kan ti o fi sita.

Télọ̀ kan ju èké fídíò nípa ìkọlù agbébọn l‘Ogun sórí ayélujára láti pawó, ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ fún-un

Télọ̀ kan ju èké fídíò nípa ìkọlù agbébọn l‘Ogun sórí ayélujára láti pawó, ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ fún-un

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 26 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 05:54:06

Ninu fidio naa ni wọn ti ṣafihan ikọlu kan , ti wọn si n sọ pe awon agbebọn ti wọ Atan Ota, ipinlẹ Ogun.

Ìgbésẹ̀ tó dáa ni ikọ̀ Ìrù Ẹkùn ti Sunday Igboho dá sílẹ̀, àmọ́ ìbọn kò gbọdọ̀ di tọ́rọ́ fọ́n kálé láàrin ilú - Onímọ̀ ààbò

Ìgbésẹ̀ tó dáa ni ikọ̀ Ìrù Ẹkùn ti Sunday Igboho dá sílẹ̀, àmọ́ ìbọn kò gbọdọ̀ di tọ́rọ́ fọ́n kálé láàrin ilú - Onímọ̀ ààbò

Ọjọ́ Ajé, 25 Oṣù Ẹ̀bibi 2026 ní 13:45:52

Ni bayii, Igboho ti n pe fun awọn ọmọ Yoruba tootọ to ba ṣetan lati darapọ mọ ikọ naa pe ki wọn maa bọ wa.