
Ọjọ́ Àìkú, 21 Oṣù Òkúdu 2026 ní 09:26:48
Atẹjade ti alaga ẹgbẹ oṣelu AAC tẹka ipinle Ekiti, Makinde Folorunso fi lede lọjọ Abamẹta, Ogunjọ, oṣu Kẹfa lẹyin ti eto idibo naa pari fẹsun kan pe awọn iwa ko tọ to waye nibi eto idbo naa ko kere.

Ọjọ́ Àìkú, 21 Oṣù Òkúdu 2026 ní 12:48:15
Fidio kan to wa lori ayelujara ṣafihan bawọn eeyan ṣe n fi ijo pade alaboyun kan, aburo rẹ atawọn ọmọ rẹ ti wọn gba itusilẹ kuro ni ahamọ awọn ajinigbe to n da agbegbe naa laamu.

Ọjọ́ Àìkú, 21 Oṣù Òkúdu 2026 ní 09:50:25
Ọjọ Aiku kẹta ninu oṣu Kẹfa ni wọn maa n ṣa ayajọ naa ni ọpọ orilẹede.

Ọjọ́ Àìkú, 21 Oṣù Òkúdu 2026 ní 05:53:24
Apapọ ibo to ni jẹ 319, 224, òun sì lo ní ibo to pọ julọ ni gbogbo ìjọba ìbílẹ̀ merindinlogun to wa ni ìpínlẹ̀ Ekiti.

Ọjọ́ Àìkú, 21 Oṣù Òkúdu 2026 ní 02:29:03
Ajo INEC ti kede pe Biodun Oyebanji lo jawe olubori ninu idibo gomina nipinlẹ Ekiti to waye lojo Satide.

Ọjọ́ Àìkú, 21 Oṣù Òkúdu 2026 ní 05:12:00
Oriyomi ni bi nnkan ṣe n lọ lagbo òṣèlú nipinlẹ Oyo lọ jẹ koun sọrọ sita, papaa julọ tori awon to n dunkooko moun ati ileeṣẹ redio oun.

Ọjọ́ Àìkú, 21 Oṣù Òkúdu 2026 ní 05:24:03
Ijọba ṣalaye ninu atẹjade ti ẹka to n ri si eto ẹkọ, sayẹnsi ati imọ ijinlẹ fi sita pe kii ṣe awọn akẹkọọjade ile ẹkọ girama, ati tawọn alakọọbẹrẹ ni ijọba ti fofin de.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 20 Oṣù Òkúdu 2026 ní 12:29:19
Oluwo ni ti awọn babalawo ba kọ lati ṣe bẹẹ, oun ko gbọdọ pe babalawo kankan n halẹ mọ ẹnikankan mọ nilẹ Yoruba.

__
Ìròyìn àtìgbàdégbà nípa ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 20 Oṣù Òkúdu 2026 ní 15:02:32
Ikede yii jade ti igbimọ oluwadii eyi ti igbakeji kọmiṣọna, DCP Suleiman Kafar Bayonle, to n ri si iwadii iwa ọdaran dari jabọ iwadii wọn.

Ọjọ́ Ẹtì, 19 Oṣù Òkúdu 2026 ní 17:47:59
Bi awon ẹgbẹ oṣelu to laami-laaka ṣe n koju wahala tiwọn ni awọn ẹgbẹ alatako naa n koju rogbodiyan abẹle to n da wọn laamu.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́ Ẹtì, 19 Oṣù Òkúdu 2026 ní 14:55:31
Ọjọbọ, ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹfa ọdun 2026 yii ni igbesẹ naa waye.

Ọjọ́ Ẹtì, 19 Oṣù Òkúdu 2026 ní 09:38:12
CP Abayomi Shogunle salaye pe ileeṣẹ ọlọpaa ti fi awọn oṣiṣẹ agbofinro ranṣẹ s’awọn ibi to yẹ káàkiri ipinle Ekiti lati ṣe aridaju eto aabo to peye.

Ọjọ́ Ẹtì, 19 Oṣù Òkúdu 2026 ní 10:16:43
Adekunle bu ẹni atẹ lu bi awọn eeyan ṣe maa n kaanu awọn to n ba aisan naa finra ti wọn si maa n ro pe wọn ti gba ọjọ iku wọn.

Ọjọ́ Ẹtì, 19 Oṣù Òkúdu 2026 ní 10:05:35
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Eko, CP Tijani Fatai, funra rẹ ṣabẹwo si ọgba ile ẹkọ naa lana Ọjọru lati mọ nnkan to n ṣẹlẹ nibẹ.

Ọjọ́ Ẹtì, 19 Oṣù Òkúdu 2026 ní 10:00:22
Orilẹede naa ti di ibi ibẹru fun ọpọ eeyan to n gbe nibẹ lai jẹ pe ọmọ oniluu ni wọn.

Ọjọ́ Ẹtì, 19 Oṣù Òkúdu 2026 ní 08:30:51
Baba ọmọdebinrin naa, ọgbẹni Bright Kalu sọ pe iṣẹlẹ yi waye ni aba oko Agọti niluu Idanre lọjọ Aje, ọjọ karundinlogun, oṣu Kẹfa 2026 ọdun yi.

Ọjọ́bọ, 18 Oṣù Òkúdu 2026 ní 16:57:34
Eyi lo fa Ibẹrubojo kaakiri ilu Ilorin ti ọpọ obi ati alagbatọ si n sare kaba kaba lọ mawọn ọmọ wọn nile ẹkọ.

Ọjọ́bọ, 18 Oṣù Òkúdu 2026 ní 18:55:52
L’Ọjọru ọsẹ yii ni ile ẹjọ UK kan gbe idajọ kalẹ wi pe Diezani ko jẹbi ọkankan ninu ẹsun onikoko mẹfa to da lori riba gbigba ti wọn fi kan an.

Ọjọ́bọ, 18 Oṣù Òkúdu 2026 ní 08:28:43
Ọrọ yii jade nigba ti Alhaja Modinat n sọrọ nibi ayẹyẹ iranti ọdun mejidinlogun ti Oloye Lamidi Ariyibi Adedibu jade laye.

Ọjọ́bọ, 18 Oṣù Òkúdu 2026 ní 08:23:02
Lara awọn ẹsun ti ijọba apapọ fi kan awọn eeyan naa ni kikopa ninu igbesunmọmi, nina owo sinu owo igbesunmọ, ṣiṣe iranwọ fun awọn agbesunmọmi, ati bẹẹ bẹẹ lọ.

Ọjọ́bọ, 18 Oṣù Òkúdu 2026 ní 05:15:16
Igbakeji Aarẹ orilẹede naa, Teodoro Nguema Obiang Mangue, lo fi idi ọrọ yii mulẹ.

Ọjọ́rú, 17 Oṣù Òkúdu 2026 ní 14:39:01
Agbẹnusọ fun Gomina Ademola Adeleke, Olawale Rasheed to ba BBC News Yoruba sọrọ lori idajọ naa sọ pe ki i ṣe gomina nikan ni idajọ ọhun dun mọ, bi ko ṣe gbogbo ọmọ ipinlẹ Osun pata.

Ọjọ́rú, 17 Oṣù Òkúdu 2026 ní 10:56:43
Makinde sọrọ yii lasiko ti alẹ́nulọ́rọ̀ ori ayélujára, Very Dark Man, at’awọn ọdọ mii n ṣèwọ́de niluu Ibadan lati pe fún ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti wọn ji gbe ọhun.

Ọjọ́rú, 17 Oṣù Òkúdu 2026 ní 07:21:37
Orukọ awọn agbofinro to padanu ẹmi naa bi ijọba ipinlẹ Zamfara ṣe kede ni: Abdulrazak Musa Hassan, Auwal Ahmad ati Murtala Musa.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Òkúdu 2026 ní 08:11:14
Oriyomi ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita wi pe awọn ti wọn loun ni ibaṣepọ pẹlu Surajudeed fẹ ṣakoba fun ipolongo ibo oun ni.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Òkúdu 2026 ní 15:44:18
Ileeṣẹ ọlọpaa Oyo sọ ninu atẹjade kan to fi sita loju opo X rẹ wi pe fidio naa ati ohun to wa nibẹ ko lẹsẹ nlẹ rara.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Òkúdu 2026 ní 08:51:29
Alukoro fun ileeṣẹ ọmogun Naijiria, Ọgagun Samaila Uba, lo fọrọ yii lede lalẹ ọjọ Aje ọjọ kẹẹdogun oṣu Kẹfa yii.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 16 Oṣù Òkúdu 2026 ní 07:00:34
Awọn ọdọ to ṣe iwọde l’Osogbo sọ pe bi Ọga Ọlọpaa ipinlẹ Osun, Ibrahim Gotan, ṣe dakẹ si gbogbo rogbodiyan n to ṣẹlẹ ni ipinlẹ Osun lasiko yii ku diẹ kaato.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 16 Oṣù Òkúdu 2026 ní 11:21:05
Ninu fidio kan ti Baba Ijesha fi soju opo Instagram rẹ lo ti kede iroyin pe oun ati iyawo oun, Ceoluminee ti bi ọmọkunrin to pe orukọ rẹ ni King Kagar.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 16 Oṣù Òkúdu 2026 ní 09:28:01
Iyatọ to wa laarin ọdun musulumi ati ọdun yooku ni pe wọn ko kii ṣe e papọ pẹlu awọn yooku ati pe orukọ wọn yatọ.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Òkúdu 2026 ní 13:32:41
Olootu ijọba orilẹede Pakistan, Shehbaz Sharif, to jẹ alarena laarin orilẹede mejeji lo fi ọrọ naa lede lalẹ ọjọ Aiku.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Òkúdu 2026 ní 12:46:46
Ọga agba ajọ NSCDC, Abbas Nda Mohammed lo fi ọrọ naa lede lọjọ Aiku, ọjọ kẹrinla, osu Kẹfa, ọdun 2026 ti a wa yii ni olu ileesẹ ajọ naa lẹyin iwadii lori bi oloogbe ọhun ṣe dede dawati.

Ọjọ́ Àìkú, 14 Oṣù Òkúdu 2026 ní 14:09:32
CAN kede ọrọ naa ninu iṣẹ ti Aarẹ wọn, Archbishop Daniel Okoh, ran si gbogbo Kristẹni lonii ọjọ Aiku, ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹfa ọdun 2026.

Ọjọ́ Àìkú, 14 Oṣù Òkúdu 2026 ní 06:44:50
BBC News Yorùbá wọnú ìtàn lọ nípa ìdí tí Ọba alayé nílẹ̀ Yorùbá kìí ṣe dúró níbi tí wọn ti ń pa èèyàn tàbí fojú rí òkú.