world-service-rss

BBC News Yorùbá

Peter Okoye kéde àyípadà ọjọ́ ìbí rẹ̀ pẹ̀lú Ìbejì rẹ̀ Paul Okoye, mú ọjọ́ ìbí tuntun fúnra rẹ̀

Peter Okoye kéde àyípadà ọjọ́ ìbí rẹ̀ pẹ̀lú Ìbejì rẹ̀ Paul Okoye, mú ọjọ́ ìbí tuntun fúnra rẹ̀

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 15:03:18

Peter Okoye sọ loju opo X rẹ pe ‘‘mo n fi akoko yii sọ fun ẹyin ẹbi, ọrẹ, ati ẹyij ololufẹ mi pe mi o ni maa ṣe ayajọ ọjọ ibi mi lọjọ kejidinlogun oṣu Kọkanla mọ.

Awodi: Òrìṣà òjò tí abọrẹ̀ rẹ̀ kò gbọdọ̀ ru ẹrù tàbí ṣe aṣemáṣe pẹ̀lú obìnrin

Awodi: Òrìṣà òjò tí abọrẹ̀ rẹ̀ kò gbọdọ̀ ru ẹrù tàbí ṣe aṣemáṣe pẹ̀lú obìnrin

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 10:49:47

“Aworo Awodi to ba ṣagbere ko ni dele ba; ẹni tọwọ rẹ ba yi ẹjẹ to pa ọmọlọmọ ko ni dele. Bẹẹni!.”

Wo nǹkan mẹ́tàdínlógún tí ìjọba ti fòfin dè pé wọn ò gbọdọ̀ kò wọlé sí Naijiria mọ́ látòkè òkun

Wo nǹkan mẹ́tàdínlógún tí ìjọba ti fòfin dè pé wọn ò gbọdọ̀ kò wọlé sí Naijiria mọ́ látòkè òkun

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 11:46:04

Simẹnti, ọṣẹ, ajilẹ atawọn nnkan mi ti wa lara awọn ọja tawọn eeyan ko le ko wọle mọ bayii.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 13:50:26

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

APC kéde ₦100m bíi owó fọ́ọ̀mù ìdíje ipò ààrẹ, làwọn ọmọ Nàìjíríà bá pariwo

APC kéde ₦100m bíi owó fọ́ọ̀mù ìdíje ipò ààrẹ, làwọn ọmọ Nàìjíríà bá pariwo

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 11:04:02

Fun awon oludije to fẹ dupo aarẹ ninu APC, ₦100 million ni won gbe e si pẹlu alaye pe ọgbọn miliọnu (30m) wa fun fifi ifẹ han lati dije, nigba ti aadọrin miliọnu (₦70 million) wa fun ifanikalẹ.

Níṣojú mi báyìí ni wọ́n ṣe ṣá ọkọ mi ládàá pa ṣùgbọ́n mi ò lè pariwo kí wọ́n má bàá ṣá èmi náà-Ìyàwó olóyè Ibadan

Níṣojú mi báyìí ni wọ́n ṣe ṣá ọkọ mi ládàá pa ṣùgbọ́n mi ò lè pariwo kí wọ́n má bàá ṣá èmi náà-Ìyàwó olóyè Ibadan

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 09:13:38

Ninu ọrọ ẹgbọn Oloogbe toun naa ni ka fi orukọ bo oun laṣiiri, o ni awọn ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti mu ọkan ninu awọn afurasi darandaran naa.

Bàbá kan yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ méje àti ọmọ ọlọ́mọ kan

Bàbá kan yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ méje àti ọmọ ọlọ́mọ kan

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:45:05

Awọn ọlọpaa ibẹ ṣapejuwe ipaniyan naa bii “idaamu abele”.

Àwọn ọlọ́pàá tó ti fẹ̀yìn tì lẹ́nu iṣẹ́ ṣèwọ́de l’Abuja lórí owó ìfẹ̀yìntì sísan, gbégi dínà ilé-iṣẹ́ Ààrẹ

Àwọn ọlọ́pàá tó ti fẹ̀yìn tì lẹ́nu iṣẹ́ ṣèwọ́de l'Abuja lórí owó ìfẹ̀yìntì sísan, gbégi dínà ilé-iṣẹ́ Ààrẹ

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ìgbé 2026 ní 17:43:36

Oniruuru iwe ilewọ ni wọn mu dani to fi mọ asia orilẹede Naijiria ati asia ileeṣẹ ọlọpaa.

Irọ́ ni pé a ti dá ẹ̀yáwó tí à ń ṣe fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ dúró - NELFUND

Irọ́ ni pé a ti dá ẹ̀yáwó tí à ń ṣe fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ dúró - NELFUND

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ìgbé 2026 ní 14:58:29

Loju opo X ajọ NELFUND lo ti kede lọjọ Abamẹta to kọja, pe oun ko figba kankan gbe e jade pe oun dawọ ẹyawo duro na.

A ti yanjú aáwọ̀ láàárín Makinde àti Olubadan-Ìgbìmọ̀ ọmọ Ibadan

A ti yanjú aáwọ̀ láàárín Makinde àti Olubadan-Ìgbìmọ̀ ọmọ Ibadan

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ìgbé 2026 ní 12:41:05

Atẹjade ni CCII fi sita lo kede eyi, Aarẹ wọn, Amofin Sulaimon Ajeniyi Ajewole si buwọ lu u.

Ẹ fura o! Ayédèrú ọṣẹ ìfọyín Colgate tó lé ṣàkóbá fún ara ti wà lórí igbá káàkiri - NAFDAC

Ẹ fura o! Ayédèrú ọṣẹ ìfọyín Colgate tó lé ṣàkóbá fún ara ti wà lórí igbá káàkiri - NAFDAC

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ìgbé 2026 ní 13:23:17

Ajọ NAFDAC ni oṣiṣẹ awọn meji lo ṣabẹwo si ibi ti wọn ti n ta ayederu Colgate naa nibi ti wọn ti fi idi rẹ mulẹ pe otitọ ni ọrọ naa.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ìgbé 2026 ní 13:50:26

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ìdí rèé tí a fi ń ra màálù kan ní ₦2.5m báyìí, àwọn alápatà sàlàyé

Ìdí rèé tí a fi ń ra màálù kan ní ₦2.5m báyìí, àwọn alápatà sàlàyé

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:33:08

Alaga awọn alapata nipinlẹ Eko ṣalaye siwaju sii pe ‘‘ọkọ ayọkẹlẹ mi ti mo ra ni N2.1m lọdun 2020 ko to owo ti a fi n ra maalu kan mọ bayii.

Ṣé lóòótọ́ ni pé ìdìbó 2027 tó ń bọ̀ ló jẹ́ kí ètò ààbò mẹ́hẹ ní Naijiria? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ṣé lóòótọ́ ni pé ìdìbó 2027 tó ń bọ̀ ló jẹ́ kí ètò ààbò mẹ́hẹ ní Naijiria? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ìgbé 2026 ní 13:48:57

Nigba to n ṣalaye ajọṣepọ to wa laaarin eto aabo ati idibo, Ọmọwe Kabiru Adamu, oludasilẹ ileeṣẹ eto aabo Beacon Security sọ pe iwadii ti fi han pe ajọṣepọ wa laaarin aabo ati idibo loootọ.

Wíwẹ̀ ní àárọ̀ tàbí alẹ́: Èwo ló dára jùlọ?

Wíwẹ̀ ní àárọ̀ tàbí alẹ́: Èwo ló dára jùlọ?

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ìgbé 2026 ní 11:46:42

Fún ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn, ohun tí wọ́n máa ń kọ́kọ́ ṣe lẹ́yìn tí wọ́n bá jí ni láti bọ́ sí balùwẹ̀, kí wọ́n ṣá kànìnkànìn.

Amẹ́ríkà àti Iran ní ìjíròrò ń so èso rere àmọ́ kò tíì sí ìfẹnukò

Amẹ́ríkà àti Iran ní ìjíròrò ń so èso rere àmọ́ kò tíì sí ìfẹnukò

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ìgbé 2026 ní 10:54:00

Trump sọ fún àwọn akọ̀ròyìn ní ọjọ́ Àbámẹ́ta pé Iran ń ṣe bí wọ́n ṣe máa ń ṣe láti bíi ọdún mẹ́tàdínláàádọ́ta sẹ́yìn.

Wo ohun tí wàhálà àṣejù yóò ṣe sí àwọ̀ ara à rẹ nígbà tó bá rẹ̀ ọ́

Wo ohun tí wàhálà àṣejù yóò ṣe sí àwọ̀ ara à rẹ nígbà tó bá rẹ̀ ọ́

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ìgbé 2026 ní 08:52:17

Awọn onimọ lori bo ṣe maan rẹ eeyan si ti fidi ẹ mulẹ tipẹ, pe to ba rẹ eeyan, o ni ai daa to n ṣe fun awọ ara.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọba kì í ṣe òṣèlú, Olubadan, ẹ jáwọ́ níbẹ̀ kẹ́ ẹ má baà mú àrífín wá - Balogun Olubadan

Ọba kì í ṣe òṣèlú, Olubadan, ẹ jáwọ́ níbẹ̀ kẹ́ ẹ má baà mú àrífín wá - Balogun Olubadan

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:57:31

Balogun Olubadan tẹsiwaju pe koda to ba jẹ ọmọ bibi inu Olubadan lo fẹ gbegba oṣelu, Kabiyesi ko gbọdọ gbe e soju debi tawọn eeyan yoo fi mọ ibi ti ọba fi si.

Agbébọn pa ọkùnrin kan lọ́nà oko, jí ìyá ìyàwó tuntun àtàwọn mí-ìn gbé lọ ní Kwara

Agbébọn pa ọkùnrin kan lọ́nà oko, jí ìyá ìyàwó tuntun àtàwọn mí-ìn gbé lọ ní Kwara

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ìgbé 2026 ní 16:18:36

O ya ni lẹnu pe awọn ilu wọnyi wa ni ijọba ibilẹ mẹta otọọtọ, sibẹ awọn agbebọn yii ṣọṣẹ laaarin oru ọjọ naa mọju bii pe wọn pin ara wọn ṣe e ni.

Ademola Adeleke pe ilé ìfowópamọ́ UBA àtàwọn alága kánsù APC lẹ́jọ́

Ademola Adeleke pe ilé ìfowópamọ́ UBA àtàwọn alága kánsù APC lẹ́jọ́

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ìgbé 2026 ní 09:33:52

‎Ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin, ọdún 2024 yii ni igbẹjọ naa waye ni ile ẹjọ giga to wa niluu Osogbo lagbegbe Oke-Fia.

Dókítà bọ́ sọ́wọ́ NDLEA fún lílọ́wọ́ nínú òwò Cocaine ní ìpínlẹ̀ Ogun

Dókítà bọ́ sọ́wọ́ NDLEA fún lílọ́wọ́ nínú òwò Cocaine ní ìpínlẹ̀ Ogun

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ìgbé 2026 ní 10:27:16

Eyi di mimọ ninu atẹjade ti Agbẹnusọ NDLEA, Femi Babafemi, fi sita lọjọ Aiku, ọjọ kẹjila oṣu Kẹrin 2026.

Àdéhùn jógunómí tí Trump ṣe fún Lebanon bá Israel lójijì

Àdéhùn jógunómí tí Trump ṣe fún Lebanon bá Israel lójijì

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ìgbé 2026 ní 11:13:13

Kaakiri Israel ni wọn ti n ṣiyemeji lori idi ti olori ilu naa fi tọwọ bọwe adedun onigbedeke naa.

Àlàyé lórí báwọn olùjọ́sìn tó ní ìpèníjà etí ṣé máa ń ṣiṣẹ́ Hajj ní Mecca

Àlàyé lórí báwọn olùjọ́sìn tó ní ìpèníjà etí ṣé máa ń ṣiṣẹ́ Hajj ní Mecca

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ìgbé 2026 ní 16:05:22

Lọdọọdun ni ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu olujọsin maa n lọ si orilẹede Saudi Arabia lati lọ fun Umrah, iṣẹ ijọsin tawọn eeyan maa n ṣe yatọ si Hajj

Ṣé ó yẹ kí àwọn obìnrin máa fi ẹ̀yìn sùn tí wọ́n bá fẹ́ bímọ?

Ṣé ó yẹ kí àwọn obìnrin máa fi ẹ̀yìn sùn tí wọ́n bá fẹ́ bímọ?

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:48:07

Lọdun bii ọọdunrun si irinwo ọdun ti obinrin n bimọ pẹlu idubulẹ, ọkunrin ọmọ ilẹ France kan; François Mauriceau lo fa a.

Agbẹ̀bí méjì kó sí gbaga ọlọ́pàá l’Ondo lẹ́yìn ikú ìyá àtì ọmọ tuntun jòjòló méjì

Agbẹ̀bí méjì kó sí gbaga ọlọ́pàá l'Ondo lẹ́yìn ikú ìyá àtì ọmọ tuntun jòjòló méjì

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ìgbé 2026 ní 07:58:20

Iṣẹlẹ meji ọtọtọ naa ti mu ki ọpọ maa kọminu lori iku ọmọde ati ipo ti ẹka eto ilera ipinlẹ Ondo wa bayii.

Ìdẹ̀rùn dé báwọn òṣìṣẹ́ l‘Ogun, wọn yóò gba ìsinmi ọjọ́ kan láàrín ọ̀sẹ̀, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá owó ọkọ̀ lóṣù

Ìdẹ̀rùn dé báwọn òṣìṣẹ́ l‘Ogun, wọn yóò gba ìsinmi ọjọ́ kan láàrín ọ̀sẹ̀, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá owó ọkọ̀ lóṣù

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ìgbé 2026 ní 10:02:58

Olori awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ogun, Kehinde Onasanya, lo kede eyi l’Ọjọbọ, ọjọ kẹrindinlogun,oṣu Kẹrin ọdun 2026.

Obìnrin tí wọ́n ṣèèṣì san N100,000 sí àṣùwọ̀n rẹ̀ kọ̀ láti dáwó padà, àwọn èèyàn gbaná jẹ

Obìnrin tí wọ́n ṣèèṣì san N100,000 sí àṣùwọ̀n rẹ̀ kọ̀ láti dáwó padà, àwọn èèyàn gbaná jẹ

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ìgbé 2026 ní 08:02:00

Chukwuebuka ké gbàjarè pé èèyàn kan tó fẹ́ owó náà fún òun, tí òun sì ṣèèṣì tẹ nọ́mbà Opay ẹlòmíràn sí orí fóònù tó sì lọ bọ́ sí akoto owó obìnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Opeyemi Faridat Awodoyin.

Àṣírí tú lórí bí ọwọ́ ọlọ́páà ṣe tẹ afurasí 33 tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì CAC Oke Isegun, Eruku ní Kwara

Àṣírí tú lórí bí ọwọ́ ọlọ́páà ṣe tẹ afurasí 33 tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì CAC Oke Isegun, Eruku ní Kwara

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:02:35

Olusọ agutan Taye Rotimi to jẹ igbakeji pasitọ ijọ naa sọ fun BBC pe oun n fẹ ki awọn agbesunmọmi naa foju wina ofin ijọba.

A gbàgbọ́ pé àlàáfíà yóò jọba ní Cameroon lẹ́yìn àbẹ̀wò Pope Leo XIV- Aráàlú

A gbàgbọ́ pé àlàáfíà yóò jọba ní Cameroon lẹ́yìn àbẹ̀wò Pope Leo XIV- Aráàlú

Ọjọ́rú, 15 Oṣù Ìgbé 2026 ní 17:44:45

Awọn olori ẹsin ati araalu rẹpẹtẹ to ti n duro de Papa naa ni wọn fi tilu-tifọn ki I kaabọ.

Kí ni Cute Abiola ṣe, tí omíjé fi ń dà lójú rẹ̀ àmọ́ tí ọ̀pọ̀ èèyàn ń sọ̀rọ̀ si?

Kí ni Cute Abiola ṣe, tí omíjé fi ń dà lójú rẹ̀ àmọ́ tí ọ̀pọ̀ èèyàn ń sọ̀rọ̀ si?

Ọjọ́bọ, 16 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:02:04

Iṣẹ abẹ ni iyawo Cute Abiola torukọ rẹ n jẹ Khudrah Mosunmola fi mọ, ko si too di pe wọn gbe e wọ yara iṣẹ abẹ naa ni oun ati ọkọ rẹ ti bẹrẹ fidio to n ṣafihan bi igbesẹ oyun naa ṣe n lọ han.

Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìjọba ṣe yọ ẹ̀sùn fifi owó ṣèrànwọ́ fún ìgbẹ́sùnmọ̀mí kúrò nínú ẹjọ́ ti Malami ń jẹ́

Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìjọba ṣe yọ ẹ̀sùn fifi owó ṣèrànwọ́ fún ìgbẹ́sùnmọ̀mí kúrò nínú ẹjọ́ ti Malami ń jẹ́

Ọjọ́bọ, 16 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:17:45

Tẹ o ba gbagbe, Malami ati ọmọ rẹ; Abdul Aziz ni wọn jọ n jẹjọ to ni i ṣe pẹlu nini nnkan ija ogun lọwọ lọna aitọ, ati ti pe wọn n ran awọn agbesunmọmi lọwọ.

Ogun Abẹ́lé Sudan: Akọ̀ròyìn tó há sínú ogun fún ọdún mẹ́ta sọ ohun tójú rẹ̀ rí

Ogun Abẹ́lé Sudan: Akọ̀ròyìn tó há sínú ogun fún ọdún mẹ́ta sọ ohun tójú rẹ̀ rí

Ọjọ́bọ, 16 Oṣù Ìgbé 2026 ní 07:25:33

Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ Sudan ni wọ́n ti fọ́nká káàkiri báyìí, àwọn míì ti sá lọ sí orílẹ̀ èdè mìíràn lójúnà àti bọ́ lọ́wọ́ ìpèníjà tó ń bá gbogbo ayé fínra.

Ibà ọ̀rẹ̀rẹ̀ (Lassa Fever) wọ ìpínlẹ̀ Oyo, wo ọ̀nà márùn-ún láti dènà rẹ̀

Ibà ọ̀rẹ̀rẹ̀ (Lassa Fever) wọ ìpínlẹ̀ Oyo, wo ọ̀nà márùn-ún láti dènà rẹ̀

Ọjọ́bọ, 16 Oṣù Ìgbé 2026 ní 11:18:40

Bí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ṣe kéde pé àrùn Ibà ọ̀rẹ̀rẹ̀ (Lassa Fever) ti wọ ìpínlẹ̀ náà, BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ ọ̀nà márùn-ún láti dènà àrùn náà.

Ipa wo ni àìsí aṣojú INEC níbi ìpàdé àpérò ADC yóò ní lórí ẹgbẹ́ òṣèlú náà?

Ipa wo ni àìsí aṣojú INEC níbi ìpàdé àpérò ADC yóò ní lórí ẹgbẹ́ òṣèlú náà?

Ọjọ́bọ, 16 Oṣù Ìgbé 2026 ní 11:53:31

Níbi ìpàdé náà ni wọ́n ti tún fọwọ́ òsì júwe ilé fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú náà kan tó fi mọ́ Nafiu Bala Gombe, ẹni tó jẹ́ alága ẹgbẹ́ náà tẹ́lẹ̀ rí, tó sì ń pe ìyànsípò David Mark gẹ́gẹ́ bí alága tuntun níjà nílé ẹjọ́ gíga.

Ìgbà ìkẹyìn tí máà díje fún ipò ààrẹ rèé, tí ń kò bá borí ìbò abẹ́nú, máa ṣe àtìlẹyìn fún ẹni tí ADC bá fà kalẹ̀ láti díje ipò ààrẹ - Atiku

Ìgbà ìkẹyìn tí máà díje fún ipò ààrẹ rèé, tí ń kò bá borí ìbò abẹ́nú, máa ṣe àtìlẹyìn fún ẹni tí ADC bá fà kalẹ̀ láti díje ipò ààrẹ - Atiku

Ọjọ́bọ, 16 Oṣù Ìgbé 2026 ní 12:24:55

Níbi ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan ni Atiku Abubakar ti sọ pé tí òun kò bá borí ipo ààrẹ níbi ètò ìdìbò ọdún 2027, òun kò ní dupò kankan mọ́.

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí mẹ́fà tó fẹ́ ju àdó olóró sí dúkìá ìjọba l’Ondo

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí mẹ́fà tó fẹ́ ju àdó olóró sí dúkìá ìjọba l'Ondo

Ọjọ́bọ, 16 Oṣù Ìgbé 2026 ní 14:10:53

Kọmiṣanna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Adebowale Lawal, lo sọrọ yii di mimọ lasiko to n ba awọn akoroyin sọrọ lonii Ọjọbọ, ọjọ kerindinlogun osu Kẹrin ọdun 2026.

“Ẹ̀yin ọ̀dọ́ tí ẹ̀ ń kún pé bí Toun Soetan ṣe ń kọrin ń di yín lọ́wọ́ láti dárà nínú ìjọ, ó ti lọ, ẹ wá dárà yín ká rí i”

"Ẹ̀yin ọ̀dọ́ tí ẹ̀ ń kún pé bí Toun Soetan ṣe ń kọrin ń di yín lọ́wọ́ láti dárà nínú ìjọ, ó ti lọ, ẹ wá dárà yín ká rí i"

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ìgbé 2026 ní 06:21:29

Ọpọlọpọ olorin ẹmi bii Bola Aarẹ, Funmi Aragbaye, Philip Adika atawọn mi-in si lo peju pesẹ sibi isinku gbajumọ akọrin ẹmi, Toun Soetan l‘Ọjọbọ.

‘Òkú mẹ́rìndínlọ́gọ́ta ni mo kà láàárín ìlú, ọ̀pọ̀ ló fọ́nká sínú igbó’

'Òkú mẹ́rìndínlọ́gọ́ta ni mo kà láàárín ìlú, ọ̀pọ̀ ló fọ́nká sínú igbó'

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 14 Oṣù Ìgbé 2026 ní 11:36:51

Bí àdó ikú látọ̀dọ̀ àwọn ológun Nàíjíríà tún ṣe balẹ̀ sórí aráàlu ní ọjà kan tó wà láàrin ààlà ilẹ̀ ìpínlẹ̀ Borno àti Yobe, BBC News Yoruba se akojọpọ awọn akoko mẹfa ti baalu ologun ti seesi kọlu araalu.

Amẹ́ríkà gbégi dínà Strait of Hormuz láti dí Iran lọ́wọ́ gbígbé epo gba ibẹ̀, China figbe ta pé ewu ń bẹ̀, bí owó epo ṣe wọ́n sí ní àgbáyé

Amẹ́ríkà gbégi dínà Strait of Hormuz láti dí Iran lọ́wọ́ gbígbé epo gba ibẹ̀, China figbe ta pé ewu ń bẹ̀, bí owó epo ṣe wọ́n sí ní àgbáyé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 14 Oṣù Ìgbé 2026 ní 10:56:15

Ijọba ilẹ Iran daba wiwọgile ipese Uranium fun ọdun marun un lati fopin si ogun to lọ lọwọ naa.

Àwọn ọmọ Iran kọminú lórí bóyá ogun Amẹ́ríkà lè tẹ̀síwájú tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ lẹ́yìn tí ìpàdé àláfíà forí ṣánpọ́n

Àwọn ọmọ Iran kọminú lórí bóyá ogun Amẹ́ríkà lè tẹ̀síwájú tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ lẹ́yìn tí ìpàdé àláfíà forí ṣánpọ́n

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 14 Oṣù Ìgbé 2026 ní 12:42:27

Ibaṣepọ ti ko dan mọran to wa laarin Iran ati Amẹrika tunbọ buru siwaju si lẹyin ti ipade alaafia laarin orilẹede mejeji to waye ni Pakistan lulẹ.