
Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:25:58
Okoya sọ eyi lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori bi o ṣe mu iṣẹ orin ati onkowo papọ, ti ki ọkan ko si di ọkan lọwọ.

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:28:00
Ikọlu yii waye ni agbegbe Kakafu nijọba ibilẹ Patigi, ti omiran si tun waye ni agbegbe Saare, ni ijọba ibilẹ Ifelodun.

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 06:47:54
Ọdun Aje yii maa n waye lọdọọdun ni Ile Ife nipinlẹ Osun, to si tun ti bẹrẹ lonii, ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu keji ọdun 2026.

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 11:55:13
Ipò kejìlélógóje (142) ni Nàìjíríà wà nínú àwọn orílẹ̀ èdè méjìlélọ́gọ́sàn-án (182) tí àjọ náà ṣe àgbéyẹ̀wò wọn láti mọ àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu kò wọ́pọ̀ níbẹ̀.

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 15:28:36
Wike sọ ọrọ yii niluu Abuja lasiko ọjọbi Sẹbetọ Sandy Onor, to pe ọgọta ọdun laye.

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:04:37
Ninu atẹjade kan lọjọ Aiku, agbẹnusọ ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ilẹ okere, Kimiebi Imomotimi Ebienfa, sọ pe awọn ilẹ okere kan n tan ọmọ Naijiria ẹ lati mu ki wọn lọ jagun nilẹ okeere laimọ.

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:54:46
Ileeṣẹ ọmọ ogun Israel loun ju awọn ado oloro naa lẹyin ti awọn ọmọ ogun Hamas yẹ adehun jogun-o-mi to wa laarin wọn.

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:09:57
A gbọ pe oniruru ohun ija oloro lawọn agbebọn naa ko lọwọ, bi wọn ṣe yinbọn pa awọn kan naa ni wọn fi ọbẹ rẹ ọrun awọn mii ti wọn si sọ ina si ọpọlọpọ ile ninu ikọlu ọhun.

Ọjọ́ Àìkú, 15 Oṣù Èrèlè 2026 ní 07:37:02
Ọjọ kẹta osu Keji, ọdun 2026 yii ni awọn agbebọn ṣakọlu si ilu Woro ni ijọba ibilẹ Kaiama ni ipinlẹ Kwara ti wọn si pa ọgọọrọ eeyan, wọn si tun gbe aimọye awọn obinrin ati awọn ọmọde gbe lọ.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 18:22:46
Ayajọ naa bẹrẹ pẹlu awọn ọmọlẹyin Kristi nigba ti wọn maa n ranti agbaọjẹ kan ninu igbagbọ ti wọn n pe orukọ rẹ St. Valentine ẹni ti wọn gbagbọ wi pe o fi ifẹ han sawọn eeyan.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 15:09:30
INEC ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita eyi ti ọkan lara awọn ọga agba ajọ naa, Muhammed Kudu Haruna, buwọlu wi pe asiko to wa ninu iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999 ni awọn fi ṣe agbekalẹ ọjọ idibo ọhun.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:41:41
Aṣọ yii ni wọn fi siliki dudu ṣe, Kiswa jẹ aṣọ to ni awọn akọle Al-Qur’an lara ti wọn kọ pẹlu wura ati fadaka. O bo gbogbo awọn odi ode mẹrin ti Kaaba, eto okuta ni aarin Mossalassi nla ni Mekka.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 14 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:31:22
Awọn ilu mẹta ti wọn kọ iwe ọhun si ni ilu Ira, Inaja ati Hahọ.

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 19:28:27
Igbakeji gomina Oyo, Bayo Lawal to soju fún Makinde lo gbe ọ̀pá àṣẹ fún àwọn baalẹ tó di ọba náà.

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 15:01:02
Tẹ o ba gbagbe, irọlẹ Ọjọru, ọjọ kọkanla osu Keji ọdun 2026 yii ni awọn agbebọn ya wọ ilu Oba Isin, nijoba ibilẹ Isin, ti wọn si ko araalu sinu ipayinkeke.

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 14:16:33
Alaga ajọ INEC, Ọjọgbọn Joash Amupitan lo fi alakalẹ eto idibo naa lede lọjọ Ẹti, ọjọ kẹtala, oṣu Keji ọdun 2026, nibi ipade oniroyin kan l’Abuja.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:44:22
Gẹgẹ bi Kọmiṣanna eto iroyin ni Kogi, Kingsley Femi Fanwo, ṣe wi, ikilọ yii n waye lati dena ikọlu awon agbebọn fun awon olujọsin lasiko ti wọn ba n ṣe isin to pẹ ju lọwọ.

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 06:02:36
Ilé ẹjọ́ ní tàbí káwọn èèyàn náà san owó ìtanràn mílíọ̀nù márùndínlọ́gọ́ta náírà.

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:01:39
Oṣere ti ọpọ eeyan mọ si Anti Ajara naa jade laye lọjọ karun-un oṣu Keji ọdun 2026 yii, lẹyin aisan to ni I ṣe pẹlu ẹdọ, to si tun wa nipo iloyun lasiko ti ọlọjọ de naa.

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:06:05
Bi iroyin naa ṣe gbode ni ọpọ eeyan n beere ohun to ṣẹlẹ ti wọn yoo fi mu El-Rufai, ko si pẹ ti El-Rufai funra ẹ fi fidi ẹ mulẹ nipasẹ Olugbani-nimọran lori iroyin rẹ, Muyiwa Adekeye.

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 13:02:59
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 13 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:01:18
Láti fi owó ṣe òdòdó, wọ́n máa ká owó, tí wọ́n sì máa to àwọn owó náà papọ̀ dáadáa láti lè jẹ́ kó dàbí òdòdó.

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:13:47
Ọpọ eeyan lo ti n beere wi pe ki ni ipade Makinde to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP ati Atiku ti i ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣelu ADC pẹlu Babangida le da le lori.

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 16:36:21
Tẹ o ba gbagbe, ṣaaju ni ikede kan ti waye lati America, pe oun yoo fi ọmọ ogun ranṣẹ silẹ yii, ti Ọgagun Samuel Uba, agbẹnusọ ileeṣẹ aabo ni Naijiria si fidi ẹ mulẹ fun BBC.

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 18:02:06
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ilu Eko ni ọkọ baaluu Arik Air Boeing 737-700 naa ti gbera, ṣugbọn ko le de Port Harcourt to n lọ to fi koju iṣoro laaarin ọna.

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 08:40:06
Ní ọjọ́ Kẹwàá, oṣù Kejì, ọdún 2026 ni aṣòfin ilẹ̀ Amẹ́ríkà, Riley Moore kéde lójú òpó X rẹ̀ pé òun àtàwọn akẹgbẹ́ òun, Chris Smith, Brian Mast àti Bill Huizenga ti gbé àbá kan dìde láti kojú bí wọ́n ṣe ń pa àwọn ọmọlẹ́yìn Kristi ní Nàìjíríà.

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:38:18
Ọpọ iroyin lo jade lọjọ Aje pe Usman kọwe fipo rẹ silẹ nitori ọpọ ẹsun ti wọn fi kan.

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:36:51
Ni ọjọ Kejila, oṣu Keji ọdun 2026 ni iroyin gba ori ayelujara kan wi pe awọn ọlọpaa Kwara nawọ gan afurasi kan to n ṣe bii onibara.

Ọjọ́rú, 11 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:24:09
Tinubu ni oun naa ti n gbe awọn igbesẹ akin lori ọrọ aje eyi ti yoo jẹ ki araalu gbaye gbadun.

Ọjọ́ Ajé, 16 Oṣù Èrèlè 2026 ní 11:55:13
Ipò kejìlélógóje (142) ni Nàìjíríà wà nínú àwọn orílẹ̀ èdè méjìlélọ́gọ́sàn-án (182) tí àjọ náà ṣe àgbéyẹ̀wò wọn láti mọ àwọn orílẹ̀ èdè tí ìwà àjẹbánu kò wọ́pọ̀ níbẹ̀.

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 14:49:52
Ninu alaye ọlọpaa nipa afurasi yii ni wọn ti sọ pe ìbí ọkunrin ni wọn bi i, amọ Van Rootselaar maa n pe ara rẹ ni obinrin.

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 13:44:29
Iroyin to gba ori ayelujara l’Ọjọbọ naa ṣalaye, pe ijiya to wa fun awọn to ba tabuku owo naira nipa nina a loju agbo, naa lo wa fun ẹni to ba n fi owo ṣe ododo ifẹ lati fi tọrẹ fun ololufẹ rẹ.

Ọjọ́bọ, 12 Oṣù Èrèlè 2026 ní 13:31:24
Ọkan lara awọn mọlẹbi awọn ti wọn ji gbe ọgbẹni Yinka Ọmọniyi sọ fun BBC News Yoruba pe lootọ ni wọn ti yọnda awọn mẹrin naa, ti wọn si ti darapọ mọ awọn ẹbi wọn.

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Èrèlè 2026 ní 10:09:33
Tẹ o ba gbagbe, oṣu to kọja yii ni iroyin gbode, pe awọn ajinigbe ji Dokita kan, Abu Babatunde, gbe ni Auchi, ipinlẹ Edo .

Ọjọ́ Ajé, 9 Oṣù Èrèlè 2026 ní 12:54:23
Williams kede eyi lẹyin wakati diẹ ti o ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi, ọdun marindinlọgọta niluu Eko.

Ọjọ́ Ẹtì, 6 Oṣù Èrèlè 2026 ní 14:35:41
Ẹgbẹ oṣiṣẹ JOHESU pinnu lati pada sẹnu isẹ nibi ipade igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ naa to waye niluu Abuja lọjọ Ẹti ọsẹ to kọja.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 10 Oṣù Èrèlè 2026 ní 09:05:34
Olubadan ṣèkìlọ̀ fáwọn darandaran káàkiri ìpínlẹ̀ náà láti jáwọ́ nínú dída ẹran jẹko ní ìta gbangba tí wọn kò bá fẹ́ kojú ìgbẹ́jọ́ ilé ẹjọ́.