world-service-rss

BBC News Yorùbá

‘Ó le fún mi gan, kí Ọlọ́run ṣíjú àánú wo àwọn èèyàn mi’

'Ó le fún mi gan, kí Ọlọ́run ṣíjú àánú wo àwọn èèyàn mi'

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 16:10:51

Nínú àtẹ̀jáde kan tó fi sórí ìkànnì X rẹ̀ lọ́jọ́bọ̀, Anthony Joshua ní ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ náà lágbára fún òun gan ṣùgbọ́n òun mọ̀ pé ó lágbára fún òbí àwọn èèyàn náà gan.

Kóòtù pàṣẹ kí ìjọba àpapọ̀ gbésẹ̀ lé dúkìá ₦213.2bn tí wọ́n tọpinpin kan Abubakar Malami fún ìgbà díẹ̀ ná

Kóòtù pàṣẹ kí ìjọba àpapọ̀ gbésẹ̀ lé dúkìá ₦213.2bn tí wọ́n tọpinpin kan Abubakar Malami fún ìgbà díẹ̀ ná

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 14:31:48

Mẹtadinlaadọta (57) ni awọn dukia naa ti wọn jẹ ile nla nla bi ile ẹjọ ṣe wi. Abubakar Malami, Abdulaziz ati Abiru—Rahman ti wọn jẹ ọmọ rẹ ni wọn si jọ fi ẹsun kiko dukia naa jọ lọna eru kan.

Kí nídìí tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Rivers fi bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ Gómìnà Fubara nípò?

Kí nídìí tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Rivers fi bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ Gómìnà Fubara nípò?

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 13:43:23

Nígbà tó ń fìdí ìgbésẹ̀ náà múlẹ̀ pẹ̀lú ìwé òfin Nàìjíríà, Olórí ọmọ ilé tó pọ̀ jùlọ, Major Jack ka àwọn ìwà aṣemáṣe mẹ́sàn-án tó ní ó lòdì sí òfin.

Ìdí tí iléeṣẹ́ Nestle ṣe fẹ́ dáwọn oúnjẹ ọmọdé tó tà sita padà àti bí o ṣe lè mọ oúnjẹ náà

 Ìdí tí iléeṣẹ́ Nestle ṣe fẹ́ dáwọn oúnjẹ ọmọdé tó tà sita padà àti bí o ṣe lè mọ oúnjẹ náà

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 12:04:14

'’A tọrọ aforijin lọwọ gbogbo obi, alagbatọ atawọn onibaara wa ti igbesẹ wa yii ba fa inira fun,’’ Nestle lo sọ bẹẹ.

Ìjọba mi yóò rí i dájú pé irú ìkọlù yíì kò ṣẹlẹ̀ mọ́- Gómìnà Seyi Makinde

Ìjọba mi yóò rí i dájú pé irú ìkọlù yíì kò ṣẹlẹ̀ mọ́- Gómìnà Seyi Makinde

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 10:30:37

Gomina Makinde ṣalaye pe iwadii awọn ẹṣọ alaabo fi han, pe awọn agbesunmọmi to ti ẹnu ibode ibomiran wa lo ṣe iṣẹ ibi naa.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 13:21:09

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

‘Àwọn ajínigbé dúnkokò láti gbẹ̀mí Kàbíyèsí tàbí ọmọ rẹ̀ tí wọn kò bá san N100m owó ìtúsílẹ̀’

'Àwọn ajínigbé dúnkokò láti gbẹ̀mí Kàbíyèsí tàbí ọmọ rẹ̀ tí wọn kò bá san N100m owó ìtúsílẹ̀'

Ọjọ́bọ, 1 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 10:30:20

Ẹniọwọ Ajayi ṣalaye pe kabiesi ni kawọn lọ wa ọgọ́rùn-ún kan mílíọ̀nù naira ti awọn ajinigbe naa n beere fun ni gbogbo ọna tawọn ba ti leri owo ni kawọn wa owo lọ nitori ẹmi awọn ti fẹ ẹ bọ.

Òní ni ètò ìsìnkú Allwell Ademola yóò bẹ̀rẹ̀

Òní ni ètò ìsìnkú Allwell Ademola yóò bẹ̀rẹ̀

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 07:29:24

Itẹ oku Atan, to wa ni Yaba, niluu Eko ni wọn yoo sinku si. Aago mẹwaa aarọ ni eto isinku naa yoo si waye.

Ìdìtẹ̀gbàjọba ní Burkina Faso forí sánpọ́n, Traoré móríbọ́ lọ́wọ́ ikú

Ìdìtẹ̀gbàjọba ní Burkina Faso forí sánpọ́n, Traoré móríbọ́ lọ́wọ́ ikú

Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 16:44:01

Mínísítà fún ètò ààbò Burkina Faso, Mahamadou Sana nínú ìkéde tó ṣe sọ pé ológun kan Paul Henri Damiba ló gbìyànjú ìdìtẹ̀gbàjọba tí kò kẹ́sẹ járí náà.

Kí ni òfin tí Amẹ́ríkà ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀ fáwọn tó bá fẹ́ ṣe ìrìnàjò afẹ́ tàbí lọ ra ọjà níbẹ̀ láti Nàìjíríà?

Kí ni òfin tí Amẹ́ríkà ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀ fáwọn tó bá fẹ́ ṣe ìrìnàjò afẹ́ tàbí lọ ra ọjà níbẹ̀ láti Nàìjíríà?

Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 14:40:47

Òfin yìí ló de àwọn tó bá fẹ́ gba físà B1 tàbí B2, tí wọ́n yóò sì máa san owó tí iye rẹ̀ fẹ́ẹ̀ tó mílíọ̀nù méje sí mílíọ̀nù méjìlélógún náírà ($5,000 - $15,000) kí wọ́n tó le rí físà gbà.

Ìjọba mi yóò rí i dájú pé irú ìkọlù yíì kò ṣẹlẹ̀ mọ́- Gómìnà Seyi Makinde

Ìjọba mi yóò rí i dájú pé irú ìkọlù yíì kò ṣẹlẹ̀ mọ́- Gómìnà Seyi Makinde

Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 10:30:37

Gomina Makinde ṣalaye pe iwadii awọn ẹṣọ alaabo fi han, pe awọn agbesunmọmi to ti ẹnu ibode ibomiran wa lo ṣe iṣẹ ibi naa.

Kí làwọn àtúntò tí ìjọba Nàìjíríà mú bá ètò ìdánwò WAEC àti NECO láti dènà àwọn aṣemáṣe?

Kí làwọn àtúntò tí ìjọba Nàìjíríà mú bá ètò ìdánwò WAEC àti NECO láti dènà àwọn aṣemáṣe?

Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 12:10:20

Ètò ìdánwò WAEC àti NECO ló wà fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ girama tí wọ́n wà ní ipele àṣekágbá, tí wọ́n sì ń múra láti lọ sílé ẹ̀kọ́ gíga.

Àlàyé lórí òfin tuntun tí UK gbé kalẹ̀ lórí àwọn tó ń fi ọkọ̀ ojú omi káwọn àjèjì wọlé

Àlàyé lórí òfin tuntun tí UK gbé kalẹ̀ lórí àwọn tó ń fi ọkọ̀ ojú omi káwọn àjèjì wọlé

Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 09:56:47

Awọn ẹṣọ aṣọbode yoo maa gba foonu awọn to n lo ọkọ oju omi lati japa lọ si UK ni toootọ, amọ, eyi ko tumọ si pe wọn maa fọwọ ofin mawọn eeyan naa.

Ta ni Ọ̀mọ̀wé Olugbemisola Odusote, Adarí Obìnrin àkọ́kọ́ ilé ẹ̀kọ́ gíga àwọn Amòfin tí Tinubu ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn sípò?

Ta ni Ọ̀mọ̀wé Olugbemisola Odusote, Adarí Obìnrin àkọ́kọ́ ilé ẹ̀kọ́ gíga àwọn Amòfin tí Tinubu ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn sípò?

Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 09:25:30

Atẹjade kan ti Oludamọran fun Aarẹ lori eto iroyin, Bayo Onanuga, fi sita lọjọ Iṣẹgun ana, fidi iyansipo naa mulẹ.

Àwọn orílẹ̀ èdè wo ni Trump tún ń fojúsùn lẹ́yìn Venezuela?

Àwọn orílẹ̀ èdè wo ni Trump tún ń fojúsùn lẹ́yìn Venezuela?

Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 08:01:58

Ọ̀pọ̀ àwọn orílẹ̀ èdè ni Trump ti ń fojúsùn láti ṣe ìkọlù sí.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ṣé lóòótọ́ ni pé agbébọn làwọn èèyàn mẹ́fà táwọn ọmọ ogun mú ní ìpínlẹ̀ Edo pẹ̀lú ọkọ̀ ìjọba ìbílẹ̀ Kwara?

Ṣé lóòótọ́ ni pé agbébọn làwọn èèyàn mẹ́fà táwọn ọmọ ogun mú ní ìpínlẹ̀ Edo pẹ̀lú ọkọ̀ ìjọba ìbílẹ̀ Kwara?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 15:23:41

Ninu osu Kejila, ọdun to kọja ni fọnran kan gba ori ayelujara eyi to ṣafihan awọn eeyan mẹfa kan ti wọn dọbalẹ, tawọn kan n beere nnkan lọwọ wọn.

Kí ló ń fa fàákája láàrin Wike àti akọ̀wé APC, tí Sẹ́nẹ́tọ̀ Basiru fi ní kí Wike kọ̀wé fipò mínísítà sílẹ̀? Àlàyé rèé

Kí ló ń fa fàákája láàrin Wike àti akọ̀wé APC, tí Sẹ́nẹ́tọ̀ Basiru fi ní kí Wike kọ̀wé fipò mínísítà sílẹ̀? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 12:53:39

Sẹnẹtọ Basiru ni ọrọ ti Wike sọ tabuku oun ati ọfiisi oun gẹgẹ bii akọwe agba ẹgbẹ oṣelu APC, tori nnkan toun sọ wi pe gbogbo ọmọ ẹgbẹ igbimọ amuṣẹya NWC APC gbọdọ fawọn gomina to wa nipo lọwọ ni ọwọ to tọ si wọn.

Ìyàtọ̀ láàrin òfin owó orí tuntun tó wà lákọsílẹ̀ ìjọba àti èyí tílé aṣòfin buwọ́lù, ìdí táwọn aṣòfin fi figbe ta

Ìyàtọ̀ láàrin òfin owó orí tuntun tó wà lákọsílẹ̀ ìjọba àti èyí tílé aṣòfin buwọ́lù, ìdí táwọn aṣòfin fi figbe ta

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 15:28:36

Lopin ọsẹ to kọja ni ile aṣoju-ṣofin l’Abuja fi ẹda ofin naa sita, eyi ti Aarẹ Tinubu buwọlu.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo dá olóyè Ofiki dúró lórí ìwakùsà lọ́nà àìtọ́

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo dá olóyè Ofiki dúró lórí ìwakùsà lọ́nà àìtọ́

Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 06:18:36

‎‎Ninu lẹta ti adari ẹka to n ri si ọrọ oye ni ileeṣẹ to ri n si ijọba ibilẹ ati oye jijẹ ti ipinlẹ Oyo, Olajire Moses Aloo fọwọ si fi ẹsun kan Oloye Jacob Shobaloju pe o n buwolu iwe aṣẹ fawọn ileeṣẹ kan lati maa wakusa ni awọn agbegbe kan atawọn igbo ọba lai gba aṣẹ latọdọ ijọba.

Pásítọ̀ tó ní ayé yóò parẹ́ lọ́jọ́ Kérésì, kan ọkọ̀ ńlá, dèrò àhámọ́

Pásítọ̀ tó ní ayé yóò parẹ́ lọ́jọ́ Kérésì, kan ọkọ̀ ńlá, dèrò àhámọ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 10:15:32

Bi ọjọ Keresi ṣe n sunmọle, awọn Kristẹni kan tu yaaya lọ sibi ọkọ Ebo Noah, wọn fẹ wọle ki ẹkun omi ma baa pa wọn.

Ẹ bá mi rọ Ọba Ghandi kó má tún ìtàn Ògbórí Ẹlẹ́mọ̀ṣọ́ yà- Ẹda Onile Ola

Ẹ bá mi rọ Ọba Ghandi kó má tún ìtàn Ògbórí Ẹlẹ́mọ̀ṣọ́ yà- Ẹda Onile Ola

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 07:56:41

Alagba Lere Paimo ni bi wọn ba fẹe ya itan Ogbomoso, o kunlẹ, dandan kọ ni ko jẹ Ogbori Elemọṣọ.

Àwọn ajínigbé tún jí èèyàn mẹjọ gbé ní Kwara

Àwọn ajínigbé tún jí èèyàn mẹjọ gbé ní Kwara

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 06:57:51

Iṣẹlẹ naa waye ni nnkan bi aago meje owurọ ni opopona Isanlu isin si Omu-Aran gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ.

Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, UN bu ẹnu àtẹ́ lu Amẹ́ríkà lórí ìkọlù sí Ààrẹ Venezuela

Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, UN bu ẹnu àtẹ́ lu Amẹ́ríkà lórí ìkọlù sí Ààrẹ Venezuela

Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 18:03:27

António Guterres nínú àtẹ̀jáde kan tó kà níbi ìpàdé pàjáwìrì tí àjọ náà pè lórí ìkọlù Amẹ́ríkà sí Venezuela sọ pé Trump kò tẹ̀lé òfin tó de àjọ àgbáyé lórí ìkọlù náà.

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí pásítọ̀ Chris Okafor táwọn obìnrin fẹ̀sùn kan pé ó fipá báwọn lòpọ̀

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí pásítọ̀ Chris Okafor táwọn obìnrin fẹ̀sùn kan pé ó fipá báwọn lòpọ̀

Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 19:19:36

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní pásítọ̀ náà, tó jẹ́ pásítọ̀ àgbà nínú ìjọ Mountain of Liberation and Miracles Ministries, ìpínlẹ̀ Eko máa kojú ìwádìí tó lágbára.

Lẹ́yìn oṣù mọ́kànlá, àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ padà sẹ́nu iṣẹ́ nípìnlẹ̀ Osun

Lẹ́yìn oṣù mọ́kànlá, àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ padà sẹ́nu iṣẹ́ nípìnlẹ̀ Osun

Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 16:03:42

‎‎Ti ẹ ko ba gbagbe pe, ọjọ Keje, osu Keji ọdun 2025 ni awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ ni ipinlẹ Osun ti lọ si ọfiisi gbẹyin latari ifanfa to n waye lori awọn alaga ijọba ibilẹ.

America fẹ́ẹ́ pa mi nínú ìkọlù, wọ́n ní Boko Haram ni mi-Sheikh Gumi

America fẹ́ẹ́ pa mi nínú ìkọlù, wọ́n ní Boko Haram ni mi-Sheikh Gumi

Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 12:08:41

Gumi ni America n kede pe oun fẹ gba Naijiria la, lati ba awọn agbesunmọmi ja, ṣugbọn awọn gan-an ni agbesunmọmi.

Ìjọba Kwara bẹ̀rẹ̀ ètò ìkẹ́kọ̀ọ́ lórí rédíò fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ nítorí ìkọlù àwọn ajínigbé

Ìjọba Kwara bẹ̀rẹ̀ ètò ìkẹ́kọ̀ọ́ lórí rédíò fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ nítorí ìkọlù àwọn ajínigbé

Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 17:13:55

Olohungbebe ní dídá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ dúró sílé láwọn agbègbè tí ètò ààbò ti nílò àmójútó níbẹ̀ gidi jẹ́ ọ̀nà láti fi dá ààbò bo àwọn olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ní agbègbè náà.

Àwọn agbébọn yawọ ọjà, ṣekúpa èèyàn 30, jí ọ̀pọ̀ gbé lọ

Àwọn agbébọn yawọ ọjà, ṣekúpa èèyàn 30, jí ọ̀pọ̀ gbé lọ

Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 13:34:46

Àtẹ̀jáde kan tí agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Niger, Wasiu Abiodun fi léde lọ́jọ́ Àìkú, ọjọ́ Kẹrin, oṣù Kìíní fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé èèyàn tó lé ní ọgbọ̀n ni wọ́n ṣekúpa níbi ìkọlù náà.

Wo ọjọ́ tí Ramadan yóò bẹ̀rẹ̀, ọjọ́ Àjíǹde, àti àwọn ọjọ́ ìsinmi tí ìjọba yóò kéde ní 2026

Wo ọjọ́ tí Ramadan yóò bẹ̀rẹ̀, ọjọ́ Àjíǹde, àti àwọn ọjọ́ ìsinmi tí ìjọba yóò kéde ní 2026

Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 14:45:31

Yatọ si awọn eyi tijọba yoo kede awọn miiran wa to ṣe pe ikede kankan ko ni waye lori wọn sugbọn awọn eeyan yoo ṣami wọn tori pe ọjọ pataki ni fun wọn.

Makinde ṣe àtúntò ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba Ìpínlẹ̀ Oyo, yọ Akọ̀wé ìjọba nípò

Makinde ṣe àtúntò ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba Ìpínlẹ̀ Oyo, yọ Akọ̀wé ìjọba nípò

Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 09:53:21

Gẹgẹ bi atẹjade kan ti oludamọran gomina lori eto iroyin Sulaimon Olanrewaju fi sita; Makinde ti yọ akọwe ijọba ipinlẹ Oyo, Ọjọgbọn Olanike Kudirat Adeyemo atawọn mii nipo.

Ààrẹ Tinubu pàṣẹ káwọn olórí ogun wá àwọn agbébọn tó pa èèyàn tó lé lógójì nípìnlẹ̀ Niger jáde

Ààrẹ Tinubu pàṣẹ káwọn olórí ogun wá àwọn agbébọn tó pa èèyàn tó lé lógójì nípìnlẹ̀ Niger jáde

Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 09:20:42

Tinubu dari aṣẹ naa si Minisita eto aabo, Olori awọn ẹṣọ alaabo, awọn ọga ologun ẹka kọọkan, ọga ọlọpaa patapata ati adari ẹka ọtẹlẹmuyẹ lorilẹede yii.

Àìrí iṣẹ́ ṣe kọ́ ló sọ mi di ẹni tó ń ṣẹ̀fẹ̀ lórí ayélujára- Folagade Banks

Àìrí iṣẹ́ ṣe kọ́ ló sọ mi di ẹni tó ń ṣẹ̀fẹ̀ lórí ayélujára- Folagade Banks

Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 07:12:02

Nipa bo ṣe n to gbogbo awon ipa ọlọkan-o-jọka pọ, Folagade sọ pe iwoye awọn ohun to n ṣẹlẹ lawujọ kọọkan loun fi n ṣe e.

Mi ò fipò sílẹ̀ nítorí mo ṣe nǹkan tí kò tọ́, ṣùgbọ́n nítorí mo bọ̀wọ̀ fún ọ́fíìsì mi-Kemi Adeosun

Mi ò fipò sílẹ̀ nítorí mo ṣe nǹkan tí kò tọ́, ṣùgbọ́n nítorí mo bọ̀wọ̀ fún ọ́fíìsì mi-Kemi Adeosun

Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 10:44:32

Saaju ninu ọrọ Adeosun lọdun 2022, o ni ojoojumọ ni òun fi ń wa ẹkún mu fún oṣù mẹ́ta láì ṣe iṣẹ́ kankan.

Trump ni US yóò máa ṣàkóso Venezuela, ṣe àtúnṣe sí ẹ̀ka epo rọ̀bì

Trump ni US yóò máa ṣàkóso Venezuela, ṣe àtúnṣe sí ẹ̀ka epo rọ̀bì

Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 09:21:16

Ọjọ Satide, ọjọ kẹta oṣu kinni ni US kọlu Venezuela pẹlu awọn ọmọ ogun, tí ọwo si tẹ Maduro ati iyawo rẹ, Cilia Flores, ti wọn si ti gbe wọn kuro ni orilẹede naa.

Kà nípa bí o ṣe lè dènà àìsàn ọkàn, ìgbàgbé láti ẹni ọgbọ̀n ọdún

Kà nípa bí o ṣe lè dènà àìsàn ọkàn, ìgbàgbé láti ẹni ọgbọ̀n ọdún

Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 08:17:01

Bi awọn onimọ ijinlẹ ti wi, nigba ti eeyan ba wọ ọgbọn ọdun ni awọn ẹya ara bii egungun ati iṣan yoo bẹrẹ si fi awọn apẹẹrẹ agba han.

Kí ló ṣokùnfà tí kò fi sí ọyẹ́ lásìkò yìí?

Kí ló ṣokùnfà tí kò fi sí ọyẹ́ lásìkò yìí?

Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 05:54:47

Gẹ́gẹ́ bí ìṣe, tó bá fi máa di ìparí oṣù Kejìlá sí ìbẹ̀rẹ̀ oṣù Kìíní ọdún, ọyẹ́ ti máa ń mú gidigidi láwọn apá ibìkan káàkiri Nàìjíríà ṣùgbọ́n èyí kò rí bẹ́ẹ̀ lọ́dún yìí rárá.

Wo bí ètò ìsìnkú Allwell Ademola yóò ṣe lọ

Wo bí ètò ìsìnkú Allwell Ademola yóò ṣe lọ

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 14:32:18

Atẹjade isinku naa kede pe isin orin onigbagbọ yoo waye l’Ọjọbọ naa lati aago mẹrin irọlẹ titi di aago mẹfa.

“Ẹní bá rokúròyín, mo wíi lórúkọ Olúwa, ọ́sán gangan làá gbọ̀’kú aró, òjijì làfọ̀n wọ̀ …”– Àgbà òṣèré tíátà, Lere Paimo wúre ọdún

"Ẹní bá rokúròyín, mo wíi lórúkọ Olúwa, ọ́sán gangan làá gbọ̀'kú aró, òjijì làfọ̀n wọ̀ …"– Àgbà òṣèré tíátà, Lere Paimo wúre ọdún

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2026 ní 08:04:53

Baba Ẹda ni nínú ọdún tuntun yìí, ojú wa ò ní rí ibi, ire la óò máa rí.