world-service-rss

BBC News Yorùbá

Àyájọ́ Ìṣẹ̀ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Ogun, Kwara, Osun, Oyo, Eko, ìdíje eré ìdárayá wáyé láàrin ẹlẹ́sìn Islam, Kìrìsítẹ́nì àti Ìbílẹ̀

Àyájọ́ Ìṣẹ̀ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Ogun, Kwara, Osun, Oyo, Eko, ìdíje eré ìdárayá wáyé láàrin ẹlẹ́sìn Islam, Kìrìsítẹ́nì àti Ìbílẹ̀

Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 09:39:36

Ijọba ipinlẹ Eko, Ogun, Osun ati Oyo ni wọn ti kede saaju pe isinmi lẹnu isẹ yoo wa lonii lati sami ọdun isẹse, bi Ijọba ipinlẹ Eko, Ogun, Osun ati Oyo ti kede isinmi lẹnu isẹ lonii lati sami ọdun isẹse. Awọn akọrin BBC News Yoruba si ti n lọ kaakiri lati maa mu iroyin wa fun yin nipa bi ọdun Isẹse se n lọ yika ilẹ Yoruba.

Razak Omotoyossi, akọni ọmọ Yorùbá tó jẹ́ agbábọ́ọ̀lù fún ilẹ̀ Benin àti ọkọ òṣèré tíátà, kú lẹ́ni ọdún 39

Razak Omotoyossi, akọni ọmọ Yorùbá tó jẹ́ agbábọ́ọ̀lù fún ilẹ̀ Benin àti ọkọ òṣèré tíátà, kú lẹ́ni ọdún 39

Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 10:42:42

Liigi bọọlu Naijiria ni Omotoyossi ti bẹrẹ gbọọlu gbọọlu gbigba ko to pa orilẹede rẹ da si ti Benin lati maa gba bọọlu fun wọn, to si di ilumọọka nibẹ.

Agbébọn ya bo Mọ́ṣálásí lásìkò ìrun Àsùbáà, èèyàn 25 kú, márún-ún míràn farapa

Agbébọn ya bo Mọ́ṣálásí lásìkò ìrun Àsùbáà, èèyàn 25 kú, márún-ún míràn farapa

Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 07:10:12

Ni idaji ana ọjọ Isẹgun, ni deede ago mẹfa aarọ ku isẹju mẹẹdogun, lawọn agbebọn tun ya wọ Mọsalasi kan to wa ni agbegbe Unguwan Mantau community, ni ijọba ibilẹ Malumfashi , nipinlẹ Katsina.

Kí ló dé táwọn obìnrin kan fi máa ń ní ilé ọmọ méjì, báwo ni obìnrin ṣe le mọ̀ àti ipa tó le ní lára wọn?

Kí ló dé táwọn obìnrin kan fi máa ń ní ilé ọmọ méjì, báwo ni obìnrin ṣe le mọ̀ àti ipa tó le ní lára wọn?

Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 05:57:05

Aisha Musa, ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn lati Kaduna, fihan pe aarun naawọpọ laarin awọn ọdọmọbinrin

Ìjà àgbà méjì! Aláàfin gbéná wojú Ọọ̀ni lórí òyè Ọkanlọmọ Oodua tó fi Dotun Sanusi jẹ, Ọọ̀ni, Sanusi àti ọ̀pọ̀ ọmọ Yorùbá fèsì

Ìjà àgbà méjì! Aláàfin gbéná wojú Ọọ̀ni lórí òyè Ọkanlọmọ Oodua tó fi Dotun Sanusi jẹ, Ọọ̀ni, Sanusi àti ọ̀pọ̀ ọmọ Yorùbá fèsì

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 09:40:26

Atẹjade naa ti Akọwe iroyin Alaafin, Bode Durojaiye fi sita, lo ti ni afojudi lo jẹ fun Ile Ife lati da nikan fi eeyan jẹ oye to ni i ṣe pẹlu gbogbo ilẹ Yoruba.

Ó dùn mí pé Olubadan Olakuleyin wàjà, mo rò pé yóò lò tó ọdún márùn-ún ni, mo ń sọ fúnrá mi pé ń kò tíì ṣetán láti jẹ́ Olubadan - Ladoja

Ó dùn mí pé Olubadan Olakuleyin wàjà, mo rò pé yóò  lò tó ọdún márùn-ún ni, mo ń sọ fúnrá mi pé ń kò tíì ṣetán láti jẹ́ Olubadan - Ladoja

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 12:41:55

Senatọ Rashidi Ladoja ni Ifa kọ lo n yan Ọba Ibadan, owo si kọ lo n yan Ọba Ibadan, Ọlọrun ni.

Ìjọba Eko ní kí Peller, gbajúmọ̀ sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ lórí ayélujára, san owó orí ₦36m, ariwo sọ

Ìjọba Eko ní kí Peller, gbajúmọ̀ sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ lórí ayélujára, san owó orí ₦36m, ariwo sọ

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 14:16:49

Peller, ninu fọnran kan to gbe sori ayelujara, ni owo ori N36m tijọba n beere jẹ iyalẹnu fun oun, tori oun ko ro pe o yẹ ki oun san owo ori kankan.

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 13:23:02

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ìrọ̀rùn dé báwọn àgbẹ̀, ẹ̀rọ Díróònù tó le fọ́n irúgbìn, omi tàbí òògùn dé àrọ́wọ́tó

Ìrọ̀rùn dé báwọn àgbẹ̀, ẹ̀rọ Díróònù tó le fọ́n irúgbìn, omi tàbí òògùn dé àrọ́wọ́tó

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 10:32:48

BBC News Yorùbá bá onímọ̀ nípa ẹ̀rọ Díróònù kan, Femi Adekoya sọ̀rọ̀, ẹni tó ṣàlàyé ìrọ̀rùn tí yóò báwọn àgbẹ̀ tí wọn bá ń lo ẹ̀rọ náà.

Kí ló dé tí wọn kò sin okù bàbá olówó lẹ́yìn ọdún mọ́kànlá tó jáde láyé?

Kí ló dé tí wọn kò sin okù bàbá olówó lẹ́yìn ọdún mọ́kànlá tó jáde láyé?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 05:57:09

Lẹyin igbẹjọ to waye fun ọpọ ọdun, wọn ko tii sin oku Harry Roy Veevers.

Alaafin ni olórí ọba ní ìpínlẹ̀ Oyo, kìí ṣe ohun tó rújú rárá, òun náà ni yóò máà jẹ Alága ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba lọ - Ọba Owoade

Alaafin ni olórí ọba ní ìpínlẹ̀ Oyo, kìí ṣe ohun tó rújú rárá, òun náà ni yóò máà jẹ Alága ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba lọ - Ọba Owoade

Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 10:52:19

BBC News Yorùbá dé ìlú Oyo láti bá Aláàfin sọ̀rọ̀ lórí ọ̀pọ̀ àwọn awuyewuye tó rọ̀ mọ́ ọ láti ìgbà tó ti gorí oyè, pàápàá, bó ṣe kan òun àti Ọọ̀ni, Bayo Adelabu àti jíjẹ alága ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba ní ìpínlẹ̀ Oyo.

Ọ̀pọ̀ èèyàn di àwátì, wọ́n dóòlà 10 nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi ní ìpínlẹ́ Sokoto

Ọ̀pọ̀ èèyàn di àwátì, wọ́n dóòlà 10 nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi ní ìpínlẹ́ Sokoto

Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 16:24:56

Iṣẹlẹ yii waye ni agbegbe Gojiyau ni ijọba ibilẹ Goronyo nipinlẹ Sokoto ti ọpọ idile lo wa ninu ibanujẹ ọkan bayii

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 13:23:02

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Àwọn ẹgbẹ́ alátakò fẹ̀sùn màgòmágó, àṣìlò agbára, kan APC nínú àtúndì ìbò, APC fèsì padà

Àwọn ẹgbẹ́ alátakò fẹ̀sùn màgòmágó, àṣìlò agbára, kan APC nínú àtúndì ìbò, APC fèsì padà

Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 11:54:29

Ẹgbẹ oṣelu PDP ati ADC, ti i ṣe ẹgbẹ alatako ṣalaye ẹdun ọkan wọn fun BBC News Yoruba l;ori atundi ibo to kọja eyi ti wọn lo ni ọwọ magomago ninu.

Ìṣẹ̀lẹ̀ Ibom Air dójú ti mí, n kò lè jáde mọ́ nínú ilé, gbogbo ayé ló ń fi ara mi ṣe ‘sticker’ - Comfort Emmanson sọ̀rọ̀ síta

Ìṣẹ̀lẹ̀ Ibom Air dójú ti mí, n kò lè jáde mọ́ nínú ilé, gbogbo ayé ló ń fi ara mi ṣe ‘sticker’ - Comfort Emmanson sọ̀rọ̀ síta

Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 11:12:59

Comfort Emmanson ti pe ileeṣẹ Ibom Air, ijọba apapọ ati ajọ to n ri si irinajo ọkọ ofurusu ni Naijiria lẹjọ lori iṣẹlẹ naa.

Wo àwọn nǹkan tí o kò le è ṣe ninú bàálù àti ìdí tí arìnrìnàjò fi gbọdọ̀ pa fóònù rẹ̀

Wo àwọn nǹkan tí o kò le è ṣe ninú bàálù àti ìdí tí arìnrìnàjò fi gbọdọ̀ pa fóònù rẹ̀

Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 05:59:48

Ọpọ iwadii lo ti fidi rẹ mulẹ pe foonu ati awọn ẹrọ mii le ṣe akoba fun baaluu lasiko irin ajo.

Ìgbésẹ̀ láti yan Awujale tuntun bẹ̀rẹ̀, ìdílé ọmọ oyè ń fápa jánú pé wọ́n ti fẹ́ yí ìtàn padà

Ìgbésẹ̀ láti yan Awujale tuntun bẹ̀rẹ̀, ìdílé ọmọ oyè ń fápa jánú pé wọ́n ti fẹ́ yí ìtàn padà

Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 08:57:08

Mọlẹbi Adeyemi ṣalaye pe ọmọ oye ni awọn, agba si lawọn pẹlu tori idile naa ni Ọba Sikiru Adetona, Awujalẹ to waja laipẹ ti wa.

Owó tíjọba àpapọ̀ jẹ́ Osun tó N6bn, gómìnà, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ àti Davido ni wọn ń pawọ́pọ̀ sanwó òṣìsẹ́ - Bode George

Owó tíjọba àpapọ̀ jẹ́ Osun tó N6bn, gómìnà, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ àti Davido ni wọn ń pawọ́pọ̀ sanwó òṣìsẹ́ - Bode George

Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 06:21:28

Awuyewuye naa gbilẹ nigba naa, ọpọ eeyan si n sọ pe ẹgbẹ oṣelu APC ni gomina Osun naa n ba sọrọ lati di ara wọn.

Makinde ṣàbẹ̀wò sí Fresh FM iléeṣẹ́ rédíò Ayefele tó jóná, ó ṣèlérí ìrànwọ́

Makinde ṣàbẹ̀wò sí Fresh FM iléeṣẹ́ rédíò Ayefele tó jóná, ó ṣèlérí ìrànwọ́

Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 06:25:46

Ina ọhun to ṣẹyọ níléeṣẹ́ redio Fresh FM ni alẹ ọjọ Ẹtì, ó sì jo irinṣẹ igbohunsafẹfẹ at’awọn ọpọlọpọ dukia mii rau rau níléeṣẹ́ redio Fresh FM.

Àṣìṣe gbá à ni bí Bàbá Osun ṣe ru igbá Osun Osogbo lọ́dún yìí, òun kọ́ ni igbá rírù kàn - Ìyá Osun

Àṣìṣe gbá à ni bí Bàbá Osun ṣe ru igbá Osun Osogbo lọ́dún yìí, òun kọ́ ni igbá rírù kàn - Ìyá Osun

Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 11:01:04

Nibi ayẹyẹ ọdun Osun Olojudo ti ilu ilu Ido-Osun to waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kejọ ọdun 2025 yii ni Yeye Osunpidan ti ṣalaye naa.

Makinde ṣàbẹ̀wò sí Fresh FM iléeṣẹ́ rédíò Ayefele tó jóná, ó ṣèlérí ìrànwọ́

Makinde ṣàbẹ̀wò sí Fresh FM iléeṣẹ́ rédíò Ayefele tó jóná, ó ṣèlérí ìrànwọ́

Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 06:25:46

Ina ọhun to ṣẹyọ níléeṣẹ́ redio Fresh FM ni alẹ ọjọ Ẹtì, ó sì jo irinṣẹ igbohunsafẹfẹ at’awọn ọpọlọpọ dukia mii rau rau níléeṣẹ́ redio Fresh FM.

Àbájáde ìpàdé Alaska fún Trump, Putin àti Ukraine

Àbájáde ìpàdé Alaska fún Trump, Putin àti Ukraine

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 14:15:55

Lẹyin ipade to fẹrẹ to wakati mẹta naa, awọn olori fi atẹjade le awọn akoroyin lọwọ, wọn ko si dahun ibeere kankan lọwọ wọn.

Ìdí tí Alaafin fi máa ń kúrò nípò ọba lásìkò ọdún Sango nílùú Oyo

Ìdí tí Alaafin fi máa ń kúrò nípò ọba lásìkò ọdún Sango nílùú Oyo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 07:56:36

Oriṣa Sango ati Alaafin Sango kii ṣe ọkan naa sugbọn itan fi idi rẹ mulẹ pe iwa Sango Orisa tawọn Yoruba gbagbọ pe o rọ wa ile aye naa lo wa lara Sango Alaafin.

Odunlade, Mr Latin, Kunle Afod àtàwọn òṣèré mii ń ṣèdárò Sunday Akinremi Chief Kanran tó jáde láyé

Odunlade, Mr Latin, Kunle Afod àtàwọn òṣèré mii ń ṣèdárò Sunday Akinremi Chief Kanran tó jáde láyé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 14:03:37

Iroyin sọ pe, agba oṣere Nollywood, Sunday Akinremi, ti ku.

‘Ìlú tó léwu láti gbé jùlọ fún àwọn obìnrin lágbáyé’

'Ìlú tó léwu láti gbé jùlọ fún àwọn obìnrin lágbáyé'

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 06:48:08

Lọwọ yii, ọpọ araalu lo ti padanu ẹmi wọn, ti wọn si ti fi ipa ba ọpọ awọn obinrin sun pẹlu.

Mọ̀ nípa àǹfààní mọ́kànlá tó wà nínú jíjẹ èso Watermelon

Mọ̀ nípa àǹfààní mọ́kànlá tó wà nínú jíjẹ èso Watermelon

Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 05:52:03

Eso kan to kun fun omi ni watermelon, bẹẹ lo si dun dáadáa lẹnu.

Pásítọ̀ tó ń fi màrìwò ọ̀pẹ na ọmọdé fún ‘ètò àdúrà’ wọ gàù ọlọ́pàá

Pásítọ̀ tó ń fi màrìwò ọ̀pẹ na ọmọdé fún 'ètò àdúrà' wọ gàù ọlọ́pàá

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 09:27:09

Ajọ to n gbogun ti ilokulo ati hihu iwa kotọ si ọmọniyan lorilẹede Naijiria, NAPTIP pẹlu ni awọn ti darapọ mọ iwadii lori iṣẹlẹ naa.

Ọwọ̀ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin kan pẹ̀lu N25 million tó fẹ́ẹ́ pín níbi ìdìbò

Ọwọ̀ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin kan pẹ̀lu N25 million tó fẹ́ẹ́ pín níbi ìdìbò

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 17:22:07

Gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe wi, o jọ pe afurasi naa fẹẹ fi owo ọhun ra ibo lọwọ awọn oludibo ni.

Folajimi Oyekunle ẹgbẹ́ PDP wọlé àtúndì ìbò aṣojú-ṣòfin l’Abuja ẹkùn Ibadan North

Folajimi Oyekunle ẹgbẹ́ PDP wọlé àtúndì ìbò aṣojú-ṣòfin l'Abuja ẹkùn Ibadan North

Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 06:58:19

Gẹgẹ bii esi ibo ti INEC kede, Họnọrebu Oyekunle ẹgbẹ PDP ri ibo 18,404, to si la Họnọrebu Adewale Olatunji ẹgbẹ oṣelu APC to ni ibo 8,312 mọlẹ.

Ṣé ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí ni APC àti PDP gẹ́gẹ́ bíi ọ̀rọ̀ ilé ẹjọ́ Canada?

Ṣé ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí ni APC àti PDP gẹ́gẹ́ bíi ọ̀rọ̀ ilé ẹjọ́ Canada?

Ọjọ́ Ẹtì, 15 Oṣù Ògún 2025 ní 14:25:13

Adajọ Phuong Ngo da igbẹjọ naa nu latari pe Egharevba ti fi akoko igba kan wa ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ri, ti ẹgbẹ naa ko si ṣe nnkankan nigba ti awọn alatilẹyin rẹ n ṣeruba araalu.

Kí ló fa gbas-gbos láàrín Pásítọ̀ Fatoyinbo ijọ COZA, ìjọ CAC àti ẹbí Olùdásílẹ́ ìjọ CAC, Apostle Ayo Babalola?

Kí ló fa gbas-gbos láàrín Pásítọ̀ Fatoyinbo ijọ COZA, ìjọ CAC àti ẹbí Olùdásílẹ́ ìjọ CAC, Apostle Ayo Babalola?

Ọjọ́ Ẹtì, 15 Oṣù Ògún 2025 ní 11:38:04

Lasiko yii, aforiji ni Pasitọ Fatoyinbo n tọrọ lẹyin ọrọ to sọ si Oloogbe Ẹni ọwọ Ayo Babalola, Oludasilẹ ati Alufaa agba ijọ Christ Apostolic Church (CAC) lagbaaye.

Wo ìdí tí ìjoba ṣe gbẹ́sẹ̀lé ìdásílẹ̀ ilé ẹ̀kọ́ gíga kankan ní Nàìjíríà fún ọdun méje

Wo ìdí tí ìjoba ṣe gbẹ́sẹ̀lé  ìdásílẹ̀ ilé ẹ̀kọ́ gíga kankan ní Nàìjíríà fún ọdun méje

Ọjọ́bọ, 14 Oṣù Ògún 2025 ní 05:43:31

Awọn ile ẹkọ ti ọrọ yii kan ni idasilẹ fasiti, ile ẹkọ gbogboniṣẹ atawọn ile ẹkọ awọn ti yoo di olukọ.

Ìjọba sàlàyé ìdí abájọ ipò ‘àmbásádọ̀’ nípa ọ̀rọ̀ ìrìnnà òfúrufú tó fún KWAM 1, ọ̀pọ̀ èèyàn fọnmú

Ìjọba sàlàyé ìdí abájọ ipò 'àmbásádọ̀' nípa ọ̀rọ̀ ìrìnnà òfúrufú tó fún KWAM 1, ọ̀pọ̀ èèyàn fọnmú

Ọjọ́bọ, 14 Oṣù Ògún 2025 ní 10:17:07

Lanaa Ọjọrun ọjọ kẹtala oṣu Kẹjọ yii ni minisita to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu ni Naijiria, Festus Keyamo (SAN), sọ loju opo X rẹ pe ijọba yoo fun KWAM 1 ni ipo aṣoju awọn ẹṣo eleto abo papakọ ofurufu.

Mo sì wà nínú ìrora, mo nílò ìtọ́jú, Comfort tó fa wàhálà pẹ̀lú Ibom Air sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tó jáde lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Kirikiri

Mo sì wà nínú ìrora, mo nílò ìtọ́jú, Comfort tó fa wàhálà pẹ̀lú Ibom Air sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tó jáde lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Kirikiri

Ọjọ́bọ, 14 Oṣù Ògún 2025 ní 12:46:50

Lanaa Ọjọru ọjọ kẹtala oṣu Kẹjọ yii ni Comfort gba itusilẹ lọgba ẹwọn nibi ti ko ba wa titi di ọjọ kẹfa oṣu Kẹwaa ọdun yii ti igbẹjọ rẹ ko ba ti waye.

Ohun tí a mọ̀ nípa àyẹ̀wò àwọn òṣìṣẹ́ 3,598 ní Nàìjíríà, lórí ẹ̀sùn fífowó ra iṣẹ́

Ohun tí a mọ̀ nípa àyẹ̀wò àwọn òṣìṣẹ́  3,598 ní Nàìjíríà, lórí ẹ̀sùn fífowó ra iṣẹ́

Ọjọ́rú, 13 Oṣù Ògún 2025 ní 12:52:30

Igbesẹ yii waye latari oniruuru ẹsun pe ọpọ eeyan lo n sanwo lati gba iṣẹ ijọba apapọ tawọn mii si n fi iṣẹ ọba ṣe kata-kara.

Ìdí tí ìjọba fi fagilé ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kan Kwam 1, mú àdínkù bá ìjìyà rẹ̀

Ìdí tí ìjọba fi fagilé ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kan Kwam 1, mú àdínkù bá ìjìyà rẹ̀

Ọjọ́rú, 13 Oṣù Ògún 2025 ní 09:42:06

Ninu atẹjade kan ti minisita to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu, Festus Keyamo (SAN) fi sita lo ti kede pe adinku yoo ba ijiya Kwam 1 lati oṣu mẹfa si oṣu kan gẹgẹ bii ijiya rẹ.