Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 09:39:36
Ijọba ipinlẹ Eko, Ogun, Osun ati Oyo ni wọn ti kede saaju pe isinmi lẹnu isẹ yoo wa lonii lati sami ọdun isẹse, bi Ijọba ipinlẹ Eko, Ogun, Osun ati Oyo ti kede isinmi lẹnu isẹ lonii lati sami ọdun isẹse. Awọn akọrin BBC News Yoruba si ti n lọ kaakiri lati maa mu iroyin wa fun yin nipa bi ọdun Isẹse se n lọ yika ilẹ Yoruba.
Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 10:42:42
Liigi bọọlu Naijiria ni Omotoyossi ti bẹrẹ gbọọlu gbọọlu gbigba ko to pa orilẹede rẹ da si ti Benin lati maa gba bọọlu fun wọn, to si di ilumọọka nibẹ.
Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 07:10:12
Ni idaji ana ọjọ Isẹgun, ni deede ago mẹfa aarọ ku isẹju mẹẹdogun, lawọn agbebọn tun ya wọ Mọsalasi kan to wa ni agbegbe Unguwan Mantau community, ni ijọba ibilẹ Malumfashi , nipinlẹ Katsina.
Ọjọ́rú, 20 Oṣù Ògún 2025 ní 05:57:05
Aisha Musa, ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn lati Kaduna, fihan pe aarun naawọpọ laarin awọn ọdọmọbinrin
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 09:40:26
Atẹjade naa ti Akọwe iroyin Alaafin, Bode Durojaiye fi sita, lo ti ni afojudi lo jẹ fun Ile Ife lati da nikan fi eeyan jẹ oye to ni i ṣe pẹlu gbogbo ilẹ Yoruba.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 12:41:55
Senatọ Rashidi Ladoja ni Ifa kọ lo n yan Ọba Ibadan, owo si kọ lo n yan Ọba Ibadan, Ọlọrun ni.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 14:16:49
Peller, ninu fọnran kan to gbe sori ayelujara, ni owo ori N36m tijọba n beere jẹ iyalẹnu fun oun, tori oun ko ro pe o yẹ ki oun san owo ori kankan.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 13:23:02
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 10:32:48
BBC News Yorùbá bá onímọ̀ nípa ẹ̀rọ Díróònù kan, Femi Adekoya sọ̀rọ̀, ẹni tó ṣàlàyé ìrọ̀rùn tí yóò báwọn àgbẹ̀ tí wọn bá ń lo ẹ̀rọ náà.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 05:57:09
Lẹyin igbẹjọ to waye fun ọpọ ọdun, wọn ko tii sin oku Harry Roy Veevers.
Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 10:52:19
BBC News Yorùbá dé ìlú Oyo láti bá Aláàfin sọ̀rọ̀ lórí ọ̀pọ̀ àwọn awuyewuye tó rọ̀ mọ́ ọ láti ìgbà tó ti gorí oyè, pàápàá, bó ṣe kan òun àti Ọọ̀ni, Bayo Adelabu àti jíjẹ alága ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 16:24:56
Iṣẹlẹ yii waye ni agbegbe Gojiyau ni ijọba ibilẹ Goronyo nipinlẹ Sokoto ti ọpọ idile lo wa ninu ibanujẹ ọkan bayii
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 19 Oṣù Ògún 2025 ní 13:23:02
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 11:54:29
Ẹgbẹ oṣelu PDP ati ADC, ti i ṣe ẹgbẹ alatako ṣalaye ẹdun ọkan wọn fun BBC News Yoruba l;ori atundi ibo to kọja eyi ti wọn lo ni ọwọ magomago ninu.
Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 11:12:59
Comfort Emmanson ti pe ileeṣẹ Ibom Air, ijọba apapọ ati ajọ to n ri si irinajo ọkọ ofurusu ni Naijiria lẹjọ lori iṣẹlẹ naa.
Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 05:59:48
Ọpọ iwadii lo ti fidi rẹ mulẹ pe foonu ati awọn ẹrọ mii le ṣe akoba fun baaluu lasiko irin ajo.
Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 08:57:08
Mọlẹbi Adeyemi ṣalaye pe ọmọ oye ni awọn, agba si lawọn pẹlu tori idile naa ni Ọba Sikiru Adetona, Awujalẹ to waja laipẹ ti wa.
Ọjọ́ Ajé, 18 Oṣù Ògún 2025 ní 06:21:28
Awuyewuye naa gbilẹ nigba naa, ọpọ eeyan si n sọ pe ẹgbẹ oṣelu APC ni gomina Osun naa n ba sọrọ lati di ara wọn.
Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 06:25:46
Ina ọhun to ṣẹyọ níléeṣẹ́ redio Fresh FM ni alẹ ọjọ Ẹtì, ó sì jo irinṣẹ igbohunsafẹfẹ at’awọn ọpọlọpọ dukia mii rau rau níléeṣẹ́ redio Fresh FM.
Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 11:01:04
Nibi ayẹyẹ ọdun Osun Olojudo ti ilu ilu Ido-Osun to waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kejọ ọdun 2025 yii ni Yeye Osunpidan ti ṣalaye naa.
Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 06:25:46
Ina ọhun to ṣẹyọ níléeṣẹ́ redio Fresh FM ni alẹ ọjọ Ẹtì, ó sì jo irinṣẹ igbohunsafẹfẹ at’awọn ọpọlọpọ dukia mii rau rau níléeṣẹ́ redio Fresh FM.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 14:15:55
Lẹyin ipade to fẹrẹ to wakati mẹta naa, awọn olori fi atẹjade le awọn akoroyin lọwọ, wọn ko si dahun ibeere kankan lọwọ wọn.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 07:56:36
Oriṣa Sango ati Alaafin Sango kii ṣe ọkan naa sugbọn itan fi idi rẹ mulẹ pe iwa Sango Orisa tawọn Yoruba gbagbọ pe o rọ wa ile aye naa lo wa lara Sango Alaafin.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 14:03:37
Iroyin sọ pe, agba oṣere Nollywood, Sunday Akinremi, ti ku.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 06:48:08
Lọwọ yii, ọpọ araalu lo ti padanu ẹmi wọn, ti wọn si ti fi ipa ba ọpọ awọn obinrin sun pẹlu.
Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 05:52:03
Eso kan to kun fun omi ni watermelon, bẹẹ lo si dun dáadáa lẹnu.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 09:27:09
Ajọ to n gbogun ti ilokulo ati hihu iwa kotọ si ọmọniyan lorilẹede Naijiria, NAPTIP pẹlu ni awọn ti darapọ mọ iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 16 Oṣù Ògún 2025 ní 17:22:07
Gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe wi, o jọ pe afurasi naa fẹẹ fi owo ọhun ra ibo lọwọ awọn oludibo ni.
Ọjọ́ Àìkú, 17 Oṣù Ògún 2025 ní 06:58:19
Gẹgẹ bii esi ibo ti INEC kede, Họnọrebu Oyekunle ẹgbẹ PDP ri ibo 18,404, to si la Họnọrebu Adewale Olatunji ẹgbẹ oṣelu APC to ni ibo 8,312 mọlẹ.
Ọjọ́ Ẹtì, 15 Oṣù Ògún 2025 ní 14:25:13
Adajọ Phuong Ngo da igbẹjọ naa nu latari pe Egharevba ti fi akoko igba kan wa ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ri, ti ẹgbẹ naa ko si ṣe nnkankan nigba ti awọn alatilẹyin rẹ n ṣeruba araalu.
Ọjọ́ Ẹtì, 15 Oṣù Ògún 2025 ní 11:38:04
Lasiko yii, aforiji ni Pasitọ Fatoyinbo n tọrọ lẹyin ọrọ to sọ si Oloogbe Ẹni ọwọ Ayo Babalola, Oludasilẹ ati Alufaa agba ijọ Christ Apostolic Church (CAC) lagbaaye.
Ọjọ́bọ, 14 Oṣù Ògún 2025 ní 05:43:31
Awọn ile ẹkọ ti ọrọ yii kan ni idasilẹ fasiti, ile ẹkọ gbogboniṣẹ atawọn ile ẹkọ awọn ti yoo di olukọ.
Ọjọ́bọ, 14 Oṣù Ògún 2025 ní 10:17:07
Lanaa Ọjọrun ọjọ kẹtala oṣu Kẹjọ yii ni minisita to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu ni Naijiria, Festus Keyamo (SAN), sọ loju opo X rẹ pe ijọba yoo fun KWAM 1 ni ipo aṣoju awọn ẹṣo eleto abo papakọ ofurufu.
Ọjọ́bọ, 14 Oṣù Ògún 2025 ní 12:46:50
Lanaa Ọjọru ọjọ kẹtala oṣu Kẹjọ yii ni Comfort gba itusilẹ lọgba ẹwọn nibi ti ko ba wa titi di ọjọ kẹfa oṣu Kẹwaa ọdun yii ti igbẹjọ rẹ ko ba ti waye.
Ọjọ́rú, 13 Oṣù Ògún 2025 ní 12:52:30
Igbesẹ yii waye latari oniruuru ẹsun pe ọpọ eeyan lo n sanwo lati gba iṣẹ ijọba apapọ tawọn mii si n fi iṣẹ ọba ṣe kata-kara.
Ọjọ́rú, 13 Oṣù Ògún 2025 ní 09:42:06
Ninu atẹjade kan ti minisita to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu, Festus Keyamo (SAN) fi sita lo ti kede pe adinku yoo ba ijiya Kwam 1 lati oṣu mẹfa si oṣu kan gẹgẹ bii ijiya rẹ.