
Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 14:25:37
Bíṣọ́ọ̀bù Ladigbolu tó jẹ́ àgbà ẹlẹ́sìn Kristẹni tó fẹ̀yìntì gẹ́gẹ́ bí Bíṣọ́ọ̀bù nínú ìjọ Methodist Church nínú ìfọ̀rọ̀wérò tó ṣe pẹ̀lú BBC News Yorùbá sọ pé òun kò rò pé ó yẹ kí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn máa dá ìjà sílẹ̀ rárá.

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 13:31:19
BBC News Yorùbá bá àwọn akẹkọ̀ọ́, ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ fásitì náà, ẹgbẹ́ alátakò àti ìjọba sọ̀rọ̀ lórí ìwọ́de náà.

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 09:31:14
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wike ṣàlàyé faw Akọroyin lórí ìdí tó ṣe lọ sórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye pẹ̀lú ológun.

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 07:58:58
Ọkan lara awọn ọmọ ile aṣòfin Ondo to ba BBC News Yorùbá sọrọ, Ifabiyi Olatunji salaye pé àwọn n beere pe ki ni ijọba fi owo ti wọn buwọ lu saaju ṣe?

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 13:27:31
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 09:31:14
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wike ṣàlàyé faw Akọroyin lórí ìdí tó ṣe lọ sórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye pẹ̀lú ológun.

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 05:26:16
Àtẹ̀jáde kan tí olórí ẹbí náà, Omolayo Aloba àti Bàbá Mohbad, Joseoh Aloba fi léde lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun lo ṣàlàyé ọ̀rọ̀ yìí.

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 14:23:30
Awọn fidio lori ayelujara lanaa ode yii, ṣafihan bi awọn eeyan to fẹ gba iṣẹ ologun naa ṣe to lọ loju opopona.

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 12:59:23
Oniṣowo nla, Phillip Ihenacho, to jẹ adari eto ile iṣẹmabaye yii lo gbe MOWAA kalẹ.

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 12:30:57
BBC News Yorùbá wà ṣe àkójọpọ̀ àwọn ọ̀nà tí obìnrin ń gba wé gèlè àti ọ̀nà márùn-ún tí ọkùnrin ń gbà gẹ fìlà pẹ̀lú ohun tí àwọn ìlànà náà túmọ̀ sí.

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 10:23:58
Agbẹnusọ fún Nyesom Wike, Lere Olayinka ti wá ṣàlàyé bí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ tó fa aáwọ náà ṣe jẹ́.

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 04:41:39
Gbajugbaja òṣèré tíátà nni, Kunle Afod lo kede ikú Baba Gebu ni ojú òpó ayélujára Instagram rẹ̀.

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 12:30:54
Onimọ nipa eto aabo, Akin Adeyi ni iwa arifin ni ọmogun oju omi tawọn eeyan n gboriyin fun yii lori ayelujara hu si Wike, to jẹ minisita orilẹede Naijiria.

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 12:57:42
Olugbani-nimọran pataki fun Gomina Makinde lori idasilẹ ilu tuntun ati igboro, Mofoluke Adebiyi, sọrọ nipa isẹlẹ naa nibi ipade awọn oluwoye awujọ to waye niluu Ibadan.

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 11:15:57
Ifẹsẹwọnṣe naa ṣe pataki fun Super Eagles nitori ohun ni yoo sọ boya wọn ṣi le kopa ninu idije ife ẹye agbaye 2026 World Cup.

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 12:36:08
Kanu lo sọ bẹẹ ninu iwe kan to fi ṣọwọ si adajọ James Omotosho ninu eyii to ti sọ pe ko si ofin to kin ẹjọ ti ijọba n ba oun ṣe lẹyin.

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 09:02:00
Adájọ́ Rita Oguguo fi bàbá náà sí àhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tí agbẹjọ́rò rẹ̀ yọjú sílé ẹjọ́ pé òun kò ṣe ẹjọ́ lórí lórí ọmọ òun tí wọ́n fi ipá bá lòpọ̀.

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 05:43:36
Lẹyin ti wọn kuna lati pedege fun idije 2026 World Cup lati ilẹ Afririka, Cameroon, DR Congo, Gabon ati Naijiria yoo koju Mococco ni ọla lati mọ ikọ agbabọọlu kan ti yoo ṣoju Afirika ninu ifẹsẹwọnsẹ lati pegede fun idije ife ẹyẹ agbaye lọdun to n bọ.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Bélú 2025 ní 12:29:36
BBC News Yorùbá lọ sáwọn ọjà yíkà ilẹ̀ Yorùbá láti mọ̀ bóyá lóòtọ́ọ́ ní ẹ̀dínwó ti bá àwọn owó èròjà oúnjẹ́, àti pé kí ló fà á, àbọ̀ ìwádìí wa rèé.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Bélú 2025 ní 09:39:07
Agbegbe eti omi Chad yii lo jẹ agbegbe kan ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbesunmọmi ti n ṣọṣẹ ti wọn si maa n gba owo ori lọwọ awọn apẹja, awọn to n ko igi atawọn darandaran.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́ Àìkú, 9 Oṣù Bélú 2025 ní 09:26:20
Awọn olorin bii Burna Boy, Wizkid ati Tyla, wa lara awọn ọmọ ilẹ Africa ti wọn fa kalẹ fun orin ilẹ Africa to dara julọ bayii.

Ọjọ́ Àìkú, 9 Oṣù Bélú 2025 ní 06:35:18
BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn kókó ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tó ti wáyé lẹ́yìn ìkéde Trump nípa Nàìjíríà.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 17:45:02
Àtẹ̀jáde kan tí ẹgbẹ́ olùkọ́, Nigeria Union of Teachers, NUT ẹ̀ka ìlú Ogbomoso fi sórí ayélujára sọ pé pẹ̀lú ọgbẹ́ ọkàn ni àwọn fi ń kẹ́dùn ikú ọ̀gbẹ́ni Adegoke tó pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lẹ́yìn táwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan lù ú bí ejò àìjẹ.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 17:03:33
Adari ajọ WHO, Tedros Adhanom Ghebreyesus ti fẹun kan awọn ileeṣẹ to n ṣe siga pe wọn n mọọmọ n fa oju awọn ọmọde mọra lati maa fa siga.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 15:33:30
Ó sọ pé ẹ̀mí àwọn èèyàn ṣe pàtàkì gidi, tó sì pàrọwà sí ìjọba àpapọ̀ láti fáwọn olórí ẹ̀ṣọ́ ààbò Nàìjíríà ní gbèdéke oṣù mẹ́ta láti fi ri pé àwọn agbéṣùmọ̀mí di ohun ìgbàgbé tàbí kí wọ́n pàdánù iṣẹ́ wọn.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 13:23:34
Agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ náà, Suleiman Yahaya Nguroje nínú àtẹ̀jáde kan tó fi léde lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, ọjọ́ Kẹjọ, oṣù Kọkànlá, ọdún 2025 júwe ìròyìn náà èyí tí ẹnìkan, Lionman Lioni gbé sórí ìkànnì Facebook rẹ̀ bí ọ̀nà láti dá ìjà ẹ̀sìn sílẹ̀.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 11:45:33
Yatọ si pe wọn fi ọwọ osi juwe ile fun Alaga tẹlẹ naa, igbimọ ti a mọ si Olowo-In-Council tun sọ pe awọn eeyan ilu Owo paapaa ko fẹ ri Omolayo nipo alaga mọ.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 10:20:12
Gomez jẹ ọmọ orilẹede Mexixo to fẹran aṣa ilẹ Yoruba to tun jẹ Babalawo.

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 06:43:24
Lyle ati Eleanor Gittens ti wọn jẹ akẹkọọ nile ẹkọ giga fasiti Clark Atlanta University pade ara wọn lọdun 1941 lọdun mẹrindinlelọgọrin sẹyin.

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 19:20:23
Igba akọkọ ree ti Aarẹ Tinubu yoo sọrọ lẹyin ti Aarẹ Amẹrika, Donald Trump dunkoko lati ko ogun wọ orilẹede Naijiria, lori ẹsun pe Kristẹni nikan ni awọn agbebọn n ṣekupa.

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 16:11:25
Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti aṣofin Asuquo Ekpeyong ni ijọba ko gbọdọ fun awọn to n ta ọti inu ọra naa laye mii mọ lati ko kuro nilẹ.

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 12:34:49
Lọdun 1982 ni ipinlẹ Karnataka fofin de aṣa yii, amọ, o si tẹsiwaju titi di oni.

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 11:52:49
Gẹgẹ bii GWR se sọ, Mary ti fẹran lati ma dirun lati igba to ti wa ni kekere, to si lero lati fi erongba rẹ fi ṣe aṣeyọri ni ọjọ Iwaju.

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 06:21:34
Lẹyin ti ile igbimọ aṣofin ijọba ibilẹ Agege tẹwọgba ikọwefipo silẹ Azeez, igbimọ naa yan Hon AbdulGaniyu Vinod Obasa gẹgẹ bii ẹni ti yoo rọpọ Azeez gẹgẹ bii alaga ijọba ibilẹ naa.

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 17:59:42
Paul Biya di aarẹ Cameroon loṣu Kọkanla ọdun 1982 lẹyin ti Aarẹ Ahmadou Ahidjo kọwe fipo silẹ.

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 15:13:23
Ni ilu Kampala,lorilẹede Uganda ni wọn ti bi Mamdani ki o to lọ si ilu New York pẹlu ẹbi rẹ nigba to jẹ ọmọ ọdun meje.

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 14:23:21
Láti bíi oṣù díẹ̀ sẹ́yìn ni àwọn olóṣèlú kan ní Washington ti ń fẹ̀sùn kàn pé àwọn alákatakítí ẹ̀sìn Islam ń mọ̀ọ́mọ̀ kojú oro sáwọn Kristẹni ní Nàìjíríà.

Ọjọ́rú, 5 Oṣù Bélú 2025 ní 15:38:04
Ijọba apapọ Naijiria ti sọ pe ko si nnkan to jọ ipanirun awọn kristẹni gẹgẹ bi Aarẹ Donald Trump Amẹrika ṣe sọ.

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 10:53:08
Bakan naa ni eeyan meji mi tun farapa yanayana lasiko ijamba naa.

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 11:42:25
Gana ni wọn ni o sọ fun awọn eeyan pe ọpọ igba ni oun n ri imaamu agba naa loju ala to n kọlu oun.

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 05:29:29
Ìwádìí BBC ṣàfihàn bí wọ́n ṣe ń fi ẹ̀tàn jẹ́ kí àwọn obìnrin Africa máa pèsè àdó olóró ní Russia.

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 09:25:22
Tinubu sọ pe ijọba n gbe igbesẹ lati pese aabo to peye fun araalu ati dukia ọmọ Naijiria.

Ọjọ́rú, 5 Oṣù Bélú 2025 ní 19:35:51
Mignot ni ajọ orilẹede Naijiria ati EU ti wa tipẹ, ti EU ko si ni tẹti si ọrọ miiran ti orilẹede mi ba sọ sita nipa Naijiria.