world-service-rss

BBC News Yorùbá

Wo orílẹ̀èdè méjìlá tí Trump fòfin dè pé wọn kò gbọdọ̀ wọ Amẹrika mọ́

Wo orílẹ̀èdè méjìlá tí Trump fòfin dè pé wọn kò gbọdọ̀ wọ Amẹrika mọ́

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 15:38:37

Ọpọ eeyan kaakiri agbaye lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọ lede lori ofin tuntun yii. Bi awọn kan ṣe n bu ẹnu atẹ lu Trump lori ọfin naa lawọn mii n sọ pe ohun to tọ ni lasiko yii.

‘N400, 000 sí 800,000 là n ra àgbò fún Ileya’

'N400, 000 sí 800,000 là n ra àgbò fún Ileya'

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 13:21:33

Gbogbo awọn ẹlẹran ti a fọrọ wa lẹnu wo lo sọ wi pe ẹran wọn lọdun yii ju ọdun to kọja lọ.

Balogun Kuku: Akọni to mú Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, bẹ̀rẹ̀ ọdún ojúde ọba, aya 65 tó ní kò jẹ́ kó gba ẹ̀sìn Kristẹni

Balogun Kuku: Akọni to mú Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, bẹ̀rẹ̀ ọdún ojúde ọba, aya 65 tó ní kò jẹ́ kó gba ẹ̀sìn Kristẹni

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:10:20

BBC Yoruba de Ijebu Ode, ti a si ba Ọgbeni Ọja tilẹ Ijebu, Olorogun Sunny Folorunso Kuku, tii se olori ẹbi Kuku sọrọ nipa itan aye baba nla rẹ, Balogun Kuku.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 13:06:56

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Wo iye tí bánkì yóò máa yọ lára káàdì ìpè rẹ báyìí, tí o bá lo USSD láti fowó ránṣẹ́ lórí fóònù

Wo iye tí bánkì yóò máa yọ lára káàdì ìpè rẹ báyìí, tí o bá lo USSD láti fowó ránṣẹ́ lórí fóònù

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 05:33:15

Eleyii yii ti bẹrẹ lati ana ọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹta oṣu Kẹfa yii, lẹyin ti ajọ NCC to n ri si eto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria pa a laṣẹ fawọn banki lati maa ṣe bẹẹ.

Tinubu buwọ́lu N2bn fún àtúnṣe agbègbè Mokwa tí ẹkùn omi bàjẹ́

Tinubu buwọ́lu N2bn fún àtúnṣe agbègbè Mokwa tí ẹkùn omi bàjẹ́

Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:48:04

Iye eeyan to ti padanu ẹmi wọn lori iṣẹlẹ yii lo ti le ni igba gẹgẹ bii ohun ti awọn alaṣẹ gbe sita.

Mo fún Hafot Yetunde Lawal lọ́rùn pa lásìkò tí mò ń bá a ní àjọṣepọ̀ lọ́wọ́ - Abdurahman Bello

Mo fún Hafot Yetunde Lawal lọ́rùn pa lásìkò tí mò ń bá a ní àjọṣepọ̀ lọ́wọ́ - Abdurahman Bello

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 14:25:00

Eyi ni ohun to sẹlẹ ni ile ẹjọ lonii lẹyin ti igbẹjọ naa bẹrẹ laago mẹsan kọja isẹju mẹfa ni ile ẹjọ giga ipinlẹ kwara labẹ adajọ Christiana Ajayi.

Ǹ jẹ́ èèyàn lè jẹ ànàmọ́ tàbí àlùbọ́sà tó ti ń hù? Àlàyé rèé

Ǹ jẹ́ èèyàn lè jẹ ànàmọ́ tàbí àlùbọ́sà tó ti ń hù? Àlàyé rèé

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 18:13:51

Ọmọwe Chris Bishop to jẹ onimọ nipa imọ ijinlẹ lori ikore oko ni fasiti Lincoln sọ pe ‘‘ewu to wa ninu anamọ to ti n hu ni kẹmika ti wọn n pe ni glycoalkaloids, eyi lo maa n jẹ ki iru anamọ bẹẹ koro lẹnu.

Ẹnìkan kọlu Oba Odidiọmọ Oladimeji tílùú Igbokoda , ó tún gé ọba létí jẹ

Ẹnìkan kọlu Oba Odidiọmọ Oladimeji tílùú Igbokoda , ó tún gé ọba létí jẹ

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 12:56:46

Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́, níbi ètò kan tí wọ́n ti fẹ́ ṣe ìfilọ́lẹ̀ sísọ ọ̀nà Igbokoda sí Okitipupa di oníbejì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé.

‘Omijé ni mo fi n wẹ ibùsùn mi lálaalẹ́ láti ìgbà tí ìgbéyàwó mi ti túká’

'Omijé ni mo fi n wẹ ibùsùn mi lálaalẹ́ láti ìgbà tí ìgbéyàwó mi ti túká'

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 15:06:37

Biola Adebayo sọ pe igbeyawo oun ti tuka

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

‘Àwọn èèyàn ma n sá, wọ́n sì má n bẹ̀rù ẹbí mi nítorí Trichoepithelioma tó mú wa’

'Àwọn èèyàn ma n sá, wọ́n sì má n bẹ̀rù ẹbí mi nítorí Trichoepithelioma tó mú wa'

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 08:26:18

Mọlẹbi to ni aisan Trichoepithelioma, aisan kan to ma n ran ninu ẹbi, ba BBC Yoruba sọrọ lori iriri wọn

Àwọn afurasí darandaran yawọ ìlú, wọ́n kún àwọn èèyàn bí ẹran

Àwọn afurasí darandaran yawọ ìlú, wọ́n kún àwọn èèyàn bí ẹran

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 09:01:06

Ìròyìn ní ọ̀pọ̀ èèyàn ló kú, táwọn míì sì farapa nígbà táwọn míì sá àsálà fún ẹ̀mí ara wọn.

Ọkùnrin kan jábọ́ láti orí ilé alájà mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n, Cocoa House nílùú Ibadan

Ọkùnrin kan jábọ́ láti orí ilé alájà mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n, Cocoa House nílùú Ibadan

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 05:50:03

Iroyin ni akẹkọọjade ilẹ ẹkọ Afe Babalola University, to wa niluu Ado Ekiti, (ABUAD) ni oloogbe ọhun, ko to maa kẹkọọ nipa imọ “cybersecurity” ni aja kẹjọ Cocoa House ṣaaju iṣẹlẹ laabi naa.

Wo bí o ṣe le dífá lọ́dọ́ babalawo láti orí fóònù rẹ láti ibikíbi l’ágbàáyé

Wo bí o ṣe le dífá lọ́dọ́ babalawo láti orí fóònù rẹ láti ibikíbi l'ágbàáyé

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 07:08:34

Olawole Olakunle, Babalawo to n jatọ ba BBC sọrọ lori ipa ti imọ ẹrọ n ko ibamu pẹlu Ifa ati awọn nnkan aṣa miiran.

‘Gbogbo ìpèníjà ètò ààbò yóò di ìgbàgbé nílùú Owo tá a bá rí irinṣẹ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ’

'Gbogbo ìpèníjà ètò ààbò yóò di ìgbàgbé nílùú Owo tá a bá rí irinṣẹ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ'

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:52:41

Kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Wilfred Olutokunbo Afolabi sọrọ lori awọn aṣeyọri ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa, ati awọn ipenija wọn

Èèyàn tó ti pàdánù ẹ̀mí wọn níbi ẹ̀kún omi Niger ti di 230, 400 di àwátì

Èèyàn tó ti pàdánù ẹ̀mí wọn níbi ẹ̀kún omi Niger ti di 230, 400 di àwátì

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 16:16:49

Iṣẹlẹ omiyale yii ni igbagbọ wa pe oun lo buru ju lorilẹede Naijiria, laarin aadọta ọdun.

Ta ló lẹ́tọ̀ọ́ láti pa ẹran Ileya?

Ta ló lẹ́tọ̀ọ́ láti pa ẹran Ileya?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 16:26:44

Ileya jẹ́ ọdún tó ṣe pàtàkì sáwọn Mùsùlùmí nítorí òhun ni wọ́n kà kún ọdún ńlá níbi tí wọ́n ti máa ń pa ẹran àgbò.

Ojú mi ni omi ṣe wọ́ ìyàwó àti ọmọ mi lọ, èèyàn mẹ́sàn-án ni èmi nìkan pàdánù nínú ẹ̀kún omi Mokwa’

Ojú mi ni omi ṣe wọ́ ìyàwó àti ọmọ mi lọ, èèyàn mẹ́sàn-án ni èmi nìkan pàdánù nínú ẹ̀kún omi Mokwa'

Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 10:31:38

Ọmọ kan ṣoṣo naa ni Adamu ṣẹṣẹ bi, o ṣalaye fun BBC pe ọmọ ikoko naa pẹlu iya rẹ to bi i foun, wa lara awọn eeyan ti omi wọ lọ latari ojo nla to rọ l’Ọjọruu mọju Ọjọbọ, nipinlẹ Niger. Eyi to fa omiyale ati ẹkun omi to bo ori awọn ile lọ.

‘Mo mọ̀ pé agbede méjì ayé àti ọ̀run ni mo wà lásìkò tí mo bá n bímọ’

'Mo mọ̀ pé agbede méjì ayé àti ọ̀run ni mo wà lásìkò tí mo bá n bímọ'

Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 10:32:17

Nàìjíríà ni orílẹ̀ èdè tó léwu jùlọ ní àgbáyé láti bímọ sí pẹ̀lú àkọ́ọ́lẹ̀ ìdá mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29%) àwọn obìnrin tó pàdánù ẹ̀mí wọn lásìkò ìbímọ káàkiri àgbáyé.

Ìdí tí àkọọ́lẹ̀ ‘writing’ àwọn dókítà ò fi kí n dùn ún wò tí kìí sí yé èèyàn

Ìdí tí àkọọ́lẹ̀ 'writing' àwọn dókítà ò fi kí n dùn ún wò tí kìí sí yé èèyàn

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 09:58:04

Kíkọ nǹkan sílẹ̀ ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú ojú àti ẹ̀yà ara tó wà fún ara yíyí.

Wo ìlú tó ti jẹ dandan fún ọkọ láti rà kẹ̀kẹ́ fún ìyàwó kí ìgbeyàwó tó ó le wáyé

Wo ìlú tó ti jẹ dandan fún ọkọ láti rà kẹ̀kẹ́ fún ìyàwó kí ìgbeyàwó tó ó le wáyé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 05:47:42

Nibi ti kẹkẹ gbayi de lọdọ awọn obinrin Askira, dandan ni ki ọkunrin to ba fẹẹ fẹ wọn ra kẹkẹ mọ ẹru obinrin ti yoo gbe niyawo.

Òbí sọ ọ̀gá ilé-ẹ̀kọ́ di èèrò iléèwòsàn lẹ́yìn tí kò jẹ́ kí ọmọ rẹ̀ jìwèé wò nínú ìdánwò WAEC l’Akure

Òbí sọ ọ̀gá ilé-ẹ̀kọ́ di èèrò iléèwòsàn lẹ́yìn tí kò jẹ́ kí ọmọ rẹ̀ jìwèé wò nínú ìdánwò WAEC l'Akure

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:15:55

Iwadii BBC YORUBA ṣafihan pe akẹkọọ naa, Elisha Wisdom n gbiyanju lati lo ẹrọ ilewọ rẹ lasiko ti ọgbẹni Rotifa gba ẹrọ ilewọ naa eyi to mu ki inu bi iya ọmọ ọhun gidigidi.

‘Pẹ̀lú ìbùsùn ní omí gbé ọ̀pọ̀ èèyàn lọ, kódà ọmọ ìyá kan nàá mẹ́rin wà lára wọn’

'Pẹ̀lú ìbùsùn ní omí gbé ọ̀pọ̀ èèyàn lọ, kódà ọmọ ìyá kan nàá mẹ́rin wà lára wọn'

Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 07:03:54

Ko din ni aadọfa eeyan ti omi gbe lọ, ti ọpọ eeyan si di alainilelori lẹyin ti agbara ojo ya wọ ile wọn nipinlẹ Niger

Iléeṣẹ́ ológun ṣèèṣì ju àdó olóró sáwọn aráàlú, àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ní kí ìjọba ṣe ìwádìí

Iléeṣẹ́ ológun ṣèèṣì ju àdó olóró sáwọn aráàlú, àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ní kí ìjọba ṣe ìwádìí

Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 17:41:29

Àwọn aráàlú ní ìpínlẹ̀ náà sọ pé ogún èèyàn ló pàdánù ẹ̀mí wọn nígbà tí iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà fi ọkọ̀ òfurufú ju àdó olóró sí ìlú náà láti fi lásìkò tí wọ́n ń gbìyànjú láti kojú ìjà sáwọn agbébọn tó wà ṣe ìkọlù sí wọn.

‘Inú yàrá ni mo tẹ́ ọmọ oṣù méjì mi sí àmọ́ inú kàǹga la ti rí òkú rẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta’

'Inú yàrá ni mo tẹ́ ọmọ oṣù méjì mi sí àmọ́ inú kàǹga la ti rí òkú rẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta'

Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 08:58:00

Nigba to n ba BBC News Yorùbá sọrọ Aishat Tahiru sọ pe, lọjọ Kẹẹdọgbọn, osu Karun un ni oun tẹ ọmọ oun to jẹ ọmọ oṣu meji ti orukọ rẹ n jẹ Adam Tahiru sinu yara lati sun, ti oun si lọ kirun lẹyinkule.

Afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn pàdé ikú òjijì lẹ́yìn eégún l’Osogbo

Afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn pàdé ikú òjijì lẹ́yìn eégún l'Osogbo

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 11:43:15

Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, DSP Abiodun Ojelabi, ṣalaye fun BBC Yoruba wi pe awọn ẹlẹgbe okunkun lo ọdun egungun to waye lagbegbe Oke Ola niluu Osogbo lati ṣe ikọlu si ara wọn.

Bàbá yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn tó rò pé ọ̀bọ ni òun rí nínú oko l’Ekiti

Bàbá yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn tó rò pé ọ̀bọ ni òun rí nínú oko l'Ekiti

Ọjọ́ Àìkú, 1 Oṣù Òkúdu 2025 ní 17:55:31

Iroyin ni ṣẹ ni ọkunrin naa ṣeṣi yinbọn pa ọmọ rẹ ọhun to jẹ ọmọ ọdun marundinlogun latari bi awọn ọbọ ṣe maa n da a lamu ninu oko rẹ.

Ìjàmbá ọkọ̀ pa eléré ìdárayá bí ogún lẹ́yìn tí wọ́n kúrò ní Gateway Games 2025

Ìjàmbá ọkọ̀ pa eléré ìdárayá bí ogún lẹ́yìn tí wọ́n kúrò ní Gateway Games 2025

Ọjọ́ Àìkú, 1 Oṣù Òkúdu 2025 ní 10:43:15

Eeyan mọkanlelogun lo padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to waye lẹyin ti wọn kuro nipinlẹ Ogun.

Nǹkan mẹ́jọ tó le mú kí obìnrin má rì í nǹkan oṣù láì lóyún

Nǹkan mẹ́jọ tó le mú kí obìnrin má rì í nǹkan oṣù láì lóyún

Ọjọ́ Àìkú, 1 Oṣù Òkúdu 2025 ní 08:25:27

Tí obìnrin kò bá rí nǹkan oṣù rẹ̀ láàárín ọjọ́ péréte tàbí tí ọjọ́ tó yẹ kó ri bá lé díẹ̀, ó ṣeéṣe kó má jẹ̀ ẹ́ ohun tó nira àmọ́ tó bá ń léra ní gbogbo ìgbà, ó nílò àmójútó, ó sì lè jẹ́ àmì àpẹẹrẹ àìsàn kan tàbí òmíràn.

Obìnrin tó lu ọmọ ara rẹ̀ ní gbànjo rí ẹ̀wọ̀n gbére he

Obìnrin tó lu ọmọ ara rẹ̀ ní gbànjo rí ẹ̀wọ̀n gbére he

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 16:49:41

Ileeṣẹ ọlọpaa ti sọ pe oun ko ni dẹkun ati maa wa ọmọde naa bo tilẹ jẹ pe awọn to ta ti gba idajọ to yẹ wọn.

Kí nídìí táwọn obìnrin kan fi máa ń jẹ olubi ọmọ lẹ́yìn ìbímọ?

Kí nídìí táwọn obìnrin kan fi máa ń jẹ olubi ọmọ lẹ́yìn ìbímọ?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:02:24

Àwọn kan gbàgbọ́ pé àwọn èròjà aṣaralóore wà nínú olubi ọmọ èyí tí ọmọ ń gbà lára ìyá rẹ̀ nínú oyún àti pé kò yẹ káwọn èròjà náà ṣòfò lẹ́yìn tí ọmọ bá dáyé tán.

Regina Chukwu sọ ìdí tí ọkọ rẹ̀ ṣe ní kò gún òun ní abẹ́rẹ́ ikú lẹ́yìn ọdún mẹ́tà ìgbéyàwó àti oṣù mẹ́rin tó bímọ

Regina Chukwu sọ ìdí tí ọkọ rẹ̀ ṣe ní kò gún òun ní abẹ́rẹ́ ikú lẹ́yìn ọdún mẹ́tà ìgbéyàwó àti oṣù mẹ́rin tó bímọ

Ọjọ́ Ẹtì, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 12:28:52

Regina Chukwu sọ pe ni kete ti oun pari ile ẹkọ girama ni oun pade ọkọ oun to jẹ ẹya Igbo nipinlẹ Anambra.

Ìtàn ayé Orúgbó, ìyá àgbà tó dá ìlú Omu-Aran sílẹ̀ ní 13th Century àmọ̀ tí wọn ‘ló wa láyé di òní’

Ìtàn ayé Orúgbó, ìyá àgbà tó dá ìlú Omu-Aran sílẹ̀ ní 13th Century àmọ̀ tí wọn ‘ló wa láyé di òní’

Ọjọ́ Ẹtì, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 11:02:36

BBC Yoruba de ilu Omu Aran nipinlẹ Kwara lati bawọn se ọdun Orugbo ti ọdun yii, ti a si gbọ ẹkunrẹrẹ itan nipa igbe aye Iya agba Orugbo.