world-service-rss

BBC News Yorùbá

Mọ̀ nípa ìrẹsì tó léwu fún ìlera rẹ tí àjọ NAFDAC ń kìlọ̀ rẹ̀

Mọ̀ nípa ìrẹsì tó léwu fún ìlera rẹ tí àjọ NAFDAC ń kìlọ̀ rẹ̀

Ọjọ́ Àìkú, 2 Oṣù Ògún 2026 ní 05:47:57

Awọn ohun to lewu gidi fun ara (metallic contamination) lo wa ninu irẹsi naa lẹyin tawọn oluwadii ṣiṣẹ lori rẹ bi NAFDAC ṣe sọ.

Okocha fi ẹ̀yìn Portable janlẹ̀ nínú ìjà ẹ̀ẹ̀kejì, Ọmọ Olalomi ṣàlàyé bó ṣe jẹ́

Okocha fi ẹ̀yìn Portable janlẹ̀ nínú ìjà ẹ̀ẹ̀kejì, Ọmọ Olalomi ṣàlàyé bó ṣe jẹ́

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 15:33:38

Tẹ o ba gbagbe, eyi ni igba keji ti awọn gbajumọ mejeeji yoo wọya ija ẹṣẹ kikan, wọn ti kọkọ jọ ja ri ni 2023 ti Portable si bori.

Wo àwọn nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Olóyè Lekan Alabi, Abese Olubadan ilẹ̀ Ibadan tó jáde láyé

Wo àwọn nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Olóyè Lekan Alabi, Abese Olubadan ilẹ̀ Ibadan tó jáde láyé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 14:34:19

Gẹgẹ bi ohun ti a gbọ, ọla ọjọ Aiku ni wọn yoo sinku Oloogbe Lekan Alabi nilana ẹsin Islam.

Ẹgbẹ̀rún kan lé nígba ni àwọn dókítà tó ṣẹ́kù l’Ógùn – NMA pariwo síta

Ẹgbẹ̀rún kan lé nígba ni àwọn dókítà tó ṣẹ́kù l'Ógùn – NMA pariwo síta

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 10:27:14

Ẹgbẹ naa ṣekilọ pe alafo naa ti ko ọpọ iṣẹ sori awọn oṣiṣẹ eleto ilera, to si ni ipinlẹ naa nilo ẹgbẹrun marun-un dokita lati pese eto ilera to pe ye.

Wo bí ìtakùrọ̀sọ BBC Yorùbá ṣe lọ láàárín àwọn olùdíje sípò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Wo bí ìtakùrọ̀sọ BBC Yorùbá ṣe lọ láàárín àwọn olùdíje sípò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 09:33:00

Oludije sipo gomina bii Ademola Adeleke, Accord; Bola Oyebamiji, APC; Najeem Salaam, ADC; Olajide Esan ti AAC; Olufẹmi Adesuyi, ZLP ati awọn miran ni BBC pe.

Nǹkan mẹ́wàá pàtàkì tí máà ṣe fún aráàlú bí mo bá di gómìnà Osun rèé- Iwaloye

Nǹkan mẹ́wàá pàtàkì tí máà ṣe fún aráàlú bí mo bá di gómìnà Osun rèé-  Iwaloye

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 10:29:58

Najeem Salaam sọ pe nnkan pataki to jẹ oun logun ni ti idagbasoke ti yoo de ba ọrọ ina mọnamọna, igbayegbadun awọn ọdọ ati oṣiṣẹ.

Ìjoba àpapọ̀ kó oògùn ìbílẹ̀ tó lè wo àìsàn jejerẹ, ẹ̀jẹ̀ ríru, jẹ̀dọ̀jẹ̀dọ̀ àtawọn àrun míì jáde

Ìjoba àpapọ̀ kó oògùn ìbílẹ̀ tó lè wo àìsàn jejerẹ, ẹ̀jẹ̀ ríru, jẹ̀dọ̀jẹ̀dọ̀ àtawọn àrun míì jáde

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 09:26:16

Ajọ Nigeria Natural Medicine Development Agency, NNMDA, lo ko awọn oogun naa jade.

Emi ò lówó tí màá fún àwọn èèyàn Osun láti dìbò fún mi o- Olajide Esan, Olùdíje sípò gómìnà fún AAC

Emi ò lówó tí màá fún àwọn èèyàn Osun láti dìbò fún mi o- Olajide Esan, Olùdíje sípò gómìnà fún AAC

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 09:31:49

Oludije yii sọ pe iṣẹ ilu ni Ọlọrun gbe le oun lọwọ, oun fẹ sin ipinlẹ Osun ni, ko ba owo de

Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá gbé ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun lọ sí ìpínlẹ̀ Osun ṣáájú ìdìbò gómìnà tó n bọ̀

Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá gbé ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun lọ sí ìpínlẹ̀ Osun ṣáájú ìdìbò gómìnà tó n bọ̀

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 10:17:48

Ọga agba pata, Olatunji Disu lo kede sita fun gbogbo Naijiria, ninu atẹjade ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Abiodun Ojelabi fi sita niluu Osogbo lọjọ Ẹti.

ÌTÀKURỌ̀SỌ LÁÀÁRÍN ÀWỌN OLÙDÍJE SÍPÒ GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ OSUN

ÌTÀKURỌ̀SỌ LÁÀÁRÍN ÀWỌN OLÙDÍJE SÍPÒ GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ OSUN

Ọjọ́ Ẹtì, 31 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:58:15

ÌTÀKURỌ̀SỌ LÁÀÁRÍN ÀWỌN OLÙDÍJE SÍPÒ GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ OSUN

Wo bí ìtakùrọ̀sọ BBC Yorùbá ṣe lọ láàárín àwọn olùdíje sípò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Wo bí ìtakùrọ̀sọ BBC Yorùbá ṣe lọ láàárín àwọn olùdíje sípò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 09:33:00

Oludije sipo gomina bii Ademola Adeleke, Accord; Bola Oyebamiji, APC; Najeem Salaam, ADC; Olajide Esan ti AAC; Olufẹmi Adesuyi, ZLP ati awọn miran ni BBC pe.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 31 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 14:36:30

Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́

Okocha fi ẹ̀yìn Portable janlẹ̀ nínú ìjà ẹ̀ẹ̀kejì, Ọmọ Olalomi ṣàlàyé bó ṣe jẹ́

Okocha fi ẹ̀yìn Portable janlẹ̀ nínú ìjà ẹ̀ẹ̀kejì, Ọmọ Olalomi ṣàlàyé bó ṣe jẹ́

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ògún 2026 ní 15:33:38

Tẹ o ba gbagbe, eyi ni igba keji ti awọn gbajumọ mejeeji yoo wọya ija ẹṣẹ kikan, wọn ti kọkọ jọ ja ri ni 2023 ti Portable si bori.

Tinubu sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ lórí ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oriire lákàtà ajínigbé, kókó ohun tó sọ rèé

Tinubu sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ lórí ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oriire lákàtà ajínigbé, kókó ohun tó sọ rèé

Ọjọ́ Ẹtì, 31 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:22:53

Aarẹ Bola Tinubu ni awọn ajinigbe naa beere owo ati itusilẹ awọn ikọ wọn to wa ni ọgba ẹwọn ki wọn too le tu awọn olukọ ati akẹkọọ to wa nigbekun wọn silẹ, ṣugbọn ijọba oun kọ jalẹ lati ṣe ohun ti wọn fẹ.

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé nílùú Ipara l’Ogun

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé nílùú Ipara l'Ogun

Ọjọ́ Ẹtì, 31 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 09:43:33

Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti wa rọ awọn obi, akẹkọọ atawọn olugbe ilu Ipara wi pe ki wọn ma foya tori pe awọn ẹṣọ eleto aabo n bẹ lori iṣẹ.

Mo máa ṣiṣẹ́ tayọ Gómìnà Adeleke àtàwọn olùdíje yòókù tí mo bá wọlé ìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun - Olùdíje AAC

Mo máa ṣiṣẹ́ tayọ Gómìnà Adeleke àtàwọn olùdíje yòókù tí mo bá wọlé ìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun - Olùdíje AAC

Ọjọ́ Ẹtì, 31 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:00:52

Oludije sipo gomina ẹgbẹ AAC ni oun loun le ṣoju araalu bi o ti tọ ati bi o ti yẹ tori oun yoo ṣejọba gẹgẹ bii adari.

DSS fi ojú afurasí márùn-ún ba ilé-ẹjọ́ lórí ìjínigbé tó wáyé l’Oyo

DSS fi ojú afurasí márùn-ún ba ilé-ẹjọ́ lórí ìjínigbé tó wáyé l'Oyo

Ọjọ́bọ, 30 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 15:52:02

Awọn maraarun yii ni DSS sọ pe awọn fura si wi pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ Jama’atu Ansarul Muslimina fi-Biladis Sudan, ti ọpọ mọ si Ansaru, ti wọn si ṣe ikọlu si awọn olukọ ati akẹkọọ nijọba ibilẹ Oriire, nipinlẹ Oyo lọjọ kẹẹdogun, oṣu Karun-un.

Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ l’Osun ṣáájú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, ọlọ́pàá mú akọ̀wé ijọba, Adeleke ní aráàlú kò ní gbà

Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ l'Osun ṣáájú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, ọlọ́pàá mú akọ̀wé ijọba, Adeleke ní aráàlú kò ní gbà

Ọjọ́bọ, 30 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:16:12

Ijọba Gómìnà Ademola Adeleke sí ti fẹsun kan ileeṣẹ ọlọpaa wi pe wọn yan ẹgbẹ oṣelu alatako sọju bi eto idibo Gomina ipinle Osun ṣe n kan ilẹkun gbọngbọn.

Ìrìnàjò mi le gan an, ìdí rèé ti mi ò fi gbádùn ayé ní kékeré - Kamo State

Ìrìnàjò mi le gan an, ìdí rèé ti mi ò fi gbádùn ayé ní kékeré - Kamo State

Ọjọ́bọ, 30 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:59:19

Kamo State sọ pe ‘‘lati igba ti mo ti wa ni kekere ni mo ti maa n ṣere ori itage, wọn maa n lo mi ninu ere ti wọn ba ti nilo ọmọ kekere.’’

Àwọn Alfa Ilorin láwọn ò fẹ́ ‘Ìrù-Ẹkùn’ tí Sunday Igboho dá sílẹ̀ ni Kwara, Ààrẹ Ìgbómìnà fèsì pé Ọ̀rọ̀ wọn kò mọ́gbọ́n wá

Àwọn Alfa Ilorin láwọn ò fẹ́ 'Ìrù-Ẹkùn' tí Sunday Igboho dá sílẹ̀ ni Kwara, Ààrẹ Ìgbómìnà fèsì pé Ọ̀rọ̀ wọn kò mọ́gbọ́n wá

Ọjọ́bọ, 30 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 07:09:57

Ti ẹ ko ba gbagbe, ni ọsẹ to kọja ni Oloye Sunday Igboho ati awọn ẹmẹwa rẹ lọ si ilu Ganmọ ni ipinlẹ Kwara lati safilọlẹ ẹgbẹ Iru Ẹkun lọna ati koju awọn agbesunmọmi ti wọn n yọ ipinlẹ naa lẹnu.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ilé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé dàwó, èèyàn méjì kú, mẹ́ta dèrò ilé ìwòsàn

Ilé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé dàwó, èèyàn méjì kú, mẹ́ta dèrò ilé ìwòsàn

Ọjọ́ Ajé, 27 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 17:34:40

Akojọpọ awọn adoola ẹmi lati ajọ Red Cross, NEMA, ileeṣẹ adoola ẹmi ipinlẹ Anambra, SEMA, ileesẹ panapa, ileeṣẹ ọlọpaa atawọn adoola ẹmi miran ni wọn wa nibẹ.

Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù

Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 28 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 09:19:42

Ṣaaju asiko yii ni Kabiesi Olubadan, Ọba Rashidi Adewolu Ladoja ti kọkọ kede ninu atẹjade kan pe ki awọn araalu, paapaa awọn obinrin, ṣora fun Egungun naa.

Mo gbọ́ pé àwọn kan láwọn fẹ́ jíbò l’Osun, eré ọmọdé ni, ìbò Osun ò ṣe é fọwọ́ kàn – Gómìnà Adeleke

Mo gbọ́ pé àwọn kan láwọn fẹ́ jíbò l'Osun, eré ọmọdé ni, ìbò Osun ò ṣe é fọwọ́ kàn – Gómìnà Adeleke

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 28 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:55:13

Oke Ila ni Gomina Adeleke ti sọrọ naa, nijọba ibilẹ Ifedayo, ipinlẹ Osun, lasiko iwọde ipolongo ibo to ku si dẹdẹ naa.

Àlàyé rèé lórí bọ́wọ́ ṣe tẹ afurasí sọ́jà tó ń ta aṣọ ọmọ ogun Naijiria fún áwọn agbésùnmọ̀mí

Àlàyé rèé lórí bọ́wọ́ ṣe tẹ afurasí sọ́jà tó ń ta aṣọ ọmọ ogun Naijiria fún áwọn agbésùnmọ̀mí

Ọjọ́ Ajé, 27 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:01:54

Afurasi naa, Mohammed Yusuf pẹlu nọmba 23NA/84/1939 Private to n ṣiṣẹ pẹlu ẹka ileeṣẹ ologun to n ran aṣọ awọn ọmogun niluu Eko ni wọn mu ni nnkan bii ago mẹfa aabọ lopin ọsẹ to kọja lẹyin iṣẹ iwadii kan ti ileeṣẹ ologun ṣe.

Ọmọ Nàìjíríà míràn tún kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá ní South Africa; Ìjọba Nàìjíríà fárígá, pè fún ìwádìí kíkún

Ọmọ Nàìjíríà míràn tún kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá ní South Africa; Ìjọba Nàìjíríà fárígá, pè fún ìwádìí kíkún

Ọjọ́ Ajé, 27 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:11:28

Tẹ o ba gbagbe, South Africa ti n le awọn ajeji rẹpẹtẹ kuro nilẹ naa o ti pẹ, paapaa awọn alawọ dudu ti wọn jẹ ọmọ Africa bii tiwọn, lori ẹsun pe wọn ko je kawọn riṣẹ ṣe niluu abinibi awọn.

Tinubu àti Atiku tún gbéná wojú ara wọn lórí ìgbẹ́jọ́ Tinubu tí iléeṣẹ́ kan gbé dìde ní Amẹ́ríkà

Tinubu àti Atiku tún gbéná wojú ara wọn lórí ìgbẹ́jọ́ Tinubu tí iléeṣẹ́ kan gbé dìde ní Amẹ́ríkà

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 13:45:42

Awuyewuye to n waye lasiko yii laaarin awọn mejeeji ko ṣẹyin bi ileeṣẹ aarẹ ṣe fẹsun kan Atiku pe o n ṣe agbatẹru ileeṣẹ kan ni Amẹrika lati lọ ṣagbedide iwadii lori igbẹjọ ti Tinubu koju ni Amẹrika lọdun 1993.

A kò tí ì fún PFIPC ní kọ́bọ̀ nínú ₦1.3bn tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún un - Ọ́fíìsì ètò ìṣúná

A kò tí ì fún PFIPC ní kọ́bọ̀ nínú ₦1.3bn tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún un - Ọ́fíìsì ètò ìṣúná

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 15:36:19

Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Keje ọdun 2026 yii ni Adari pata nileeṣẹ ijọba naa, Tanimu Yakubu, yọju si igbimọ to n tọpinpin N1.3 billion to wa ninu iṣuna ọdun 2026 fun ileeṣẹ PFIPC.

Àwọn olùgbé Akure pariwo lórí òórùn tó gbalẹ̀ kan, ìjọba bẹ̀rẹ̀ ìwádìí

Àwọn olùgbé Akure pariwo lórí òórùn tó gbalẹ̀ kan, ìjọba bẹ̀rẹ̀ ìwádìí

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:28:43

Ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo to n ri ọrọ ayika ti fidi rẹ mulẹ pe iwadii ti fi han pe oorun yii ko ṣẹyin awọn eeyan kan ti wọn n da idọti lọna aitọ sina odo to n ṣan.

Olórí àwọn tó ń pèsè owó fún ẹgbẹ agbésùnmọ̀mí ISWAP ní Naijiria jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọmọ ogun

Olórí àwọn tó ń pèsè owó fún ẹgbẹ agbésùnmọ̀mí ISWAP ní Naijiria jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọmọ ogun

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:29:42

Ninu atẹjade kan, ileeṣẹ ọmọ ogun sọ pe igbesẹ afurasi naa lo n waye lasiko ti pupọ awọn agbesunmọmi bi tirẹ bẹrẹ si n jọwọ ara wọn fun ileeṣẹ ọmọ ogun.

Ẹ wo ilé ìwòsàn táwọn aláboyún ti ń bímọ sórí ẹní

Ẹ wo ilé ìwòsàn táwọn aláboyún ti ń bímọ sórí ẹní

Ọjọ́ Ajé, 27 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:49:06

Ile iwosan alabọde Badawa ti dẹnu kọlẹ lati bi ọdun mẹwaa ti atẹgun ojo ti ba apa kan ile iwosan naa jẹ.

America kìlọ̀ fáwọn ọmọ Nàìjíríà tó tún jẹ́ ọmọ America láti má ṣe lo ìwé ìrìnná míràn yàtọ̀ sí ti orílẹ̀èdè náà láti wọlé tábì jáde l’America

America kìlọ̀ fáwọn ọmọ Nàìjíríà tó tún jẹ́ ọmọ America láti má ṣe lo ìwé ìrìnná míràn yàtọ̀ sí ti orílẹ̀èdè náà láti wọlé tábì jáde l'America

Ọjọ́ Ajé, 27 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:52:03

Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi lede loju opo X rẹ lọjọ Aiku, ni wọn ti kede pe eyi kan gbogbo ọmọ oniluu l’America pẹlu, titi kan awọn ọmọde to ba ti jẹ ọmọ oniluu meji.

Àfiwé owó oṣù àwọn ṣọ́jà Nàìjíríà pẹ̀lú àwọn akẹgbẹ́ wọn lórílẹ̀èdè míràn ní Áfíríkà

Àfiwé owó oṣù àwọn ṣọ́jà Nàìjíríà pẹ̀lú àwọn akẹgbẹ́ wọn lórílẹ̀èdè míràn ní Áfíríkà

Ọjọ́ Ajé, 27 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:59:44

Ilọpo mẹjọ ni owo oṣu awọn ọgagun lorilẹede Naijiria fi kere si ti awọn akẹgbẹ wọn lorilẹede South Africa.

Adeleke pàṣẹ kí àtúnṣe bẹ̀rẹ̀ lórí afárá tó bẹ̀rẹ̀ sí ń yẹ̀ lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ mẹ́ta tí wọ́n ṣi nílùú Osogbo

Adeleke pàṣẹ kí àtúnṣe bẹ̀rẹ̀ lórí afárá tó bẹ̀rẹ̀ sí ń yẹ̀ lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ mẹ́ta tí wọ́n ṣi nílùú Osogbo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 25 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 18:18:26

Ọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun 2026 yii ni wọn ṣi afara naa amọ o ṣeni laanu pe ko tii to ọsẹ mẹta pere ti wọn ṣi ti apakan rẹ bẹrẹ si n jin wọnu lẹyin ojo arọrọda kan.

Wo àwọn adarí ẹgbẹ́ NURTW tí wọ́n ti gbẹ̀mí wọn nílùú Eko

Wo àwọn adarí ẹgbẹ́ NURTW tí wọ́n ti gbẹ̀mí wọn nílùú Eko

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 25 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 16:19:56

Eyii ni akojọpọ awọn kan lara awọn adari NURTW ti wọn ti ṣekua niluu Eko.

Àlàyé rèé lórí bí eégún Olóòlù ṣe dé Ibadan, ìdí tí kìí fi wọ bàtà tàbí fojú kan obìnrin

Àlàyé rèé lórí bí eégún Olóòlù ṣe dé Ibadan, ìdí tí kìí fi wọ bàtà tàbí fojú kan obìnrin

Ọjọ́ Ajé, 27 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:53:12

Ní kété tí ènìyàn bá ti dárúkọ eégún Oloolu ní Ibadan, kálukú yoo máa forí gbárí, torí ẹ̀rù àti agbára tó wà lára rẹ̀

Kí ló dé tí orin K1 “Tó bá lóyún kóyún, sàárà ni” fi ń mi orí ayélujára tìtì? Àlàyé rèé

Kí ló dé tí orin K1 "Tó bá lóyún kóyún, sàárà ni" fi ń mi orí ayélujára tìtì? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 07:23:00

Arabinrin toun ni oun bimọ fun K1 sọ pe oun lọ ba mama K1 lori ọrọ ọmọ oun Azizat, mama si ṣe bi abiamọ nigba ti wọn ri ọmọ naa.

Ẹkún sọ níbí ìsìn ìrántí fún olóògbé John Olaleye olùkọ́ Oriire táwọn jàndùkú ajínigbé ṣekúpa

Ẹkún sọ níbí ìsìn ìrántí fún olóògbé John Olaleye olùkọ́ Oriire táwọn jàndùkú ajínigbé ṣekúpa

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 05:56:17

‎Ti ẹ o ba gbagbe, ọjọ Aiku akọkọ oṣu kẹfa ọdun yii ni awọn agbebon ọhun sẹkupa Ọgbẹni Olaleye, gẹgẹ bi giwa ile ẹkọ girama, Ahoro Esinele, iyẹn, Arabinrin Rachael Alamu ṣe fi idi rẹ mulẹ.

Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀

 Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 25 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:42:44

Ile tun fẹnuko nibi ijokoo wọn lonii Ọjọru niluu Abeokuta wi pe iyọnipo rẹ ti di ikọwefiposilẹ bayii.

Mi ò lérò pé mo lè dé ipò Ìmáàmù ìlú Ilorin, àmọ́, mo ti máa ń rí àwọn àpẹẹrẹ kan tipẹ́ - Ìmáàmù Ilorin tuntun

Mi ò lérò pé mo lè dé ipò Ìmáàmù ìlú Ilorin, àmọ́, mo ti máa ń rí àwọn àpẹẹrẹ kan tipẹ́ - Ìmáàmù Ilorin tuntun

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 25 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 08:51:59

Imaamu Ilorin tuntun fikun ọrọ rẹ pe awọn musulumi ko gbọdọ jẹ ki ero awọn ọta Islam to maa n sọ pe ẹsin jagidijagan ni ẹsin Islam ṣẹ mọ wọn wa lara.

Ọlọ́pàá mẹ́rin tó bèèrè owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ awakọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ọrẹ si Benin wọ gàù, ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí wọn

Ọlọ́pàá mẹ́rin tó bèèrè owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ awakọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ọrẹ si Benin wọ gàù, ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí wọn

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 25 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 11:12:16

Gẹgẹ bi kọmandi ọlọpaa Ondo ṣe wi loju opo X, wọn ti mọ awọn ọlọpaa to wa ninu fidio yii, iwadii ati igbesẹ to yẹ si ti bẹrẹ lorii wọn.

Kókó ìpàdé Sẹ́nẹ́tọ̀ Folarin pẹ̀lú Ààrẹ Tinubu lórí awuyewuye nípa olùdíje sípò gómìnà fẹ́gbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Oyo

Kókó ìpàdé Sẹ́nẹ́tọ̀ Folarin pẹ̀lú Ààrẹ Tinubu lórí awuyewuye nípa olùdíje sípò gómìnà fẹ́gbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Oyo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 25 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 12:46:58

Ipade naa ni wọn lo da lori erongba lati fi opin si gbogbo aawọ, wahala ati ikunsinu to wa laaarin awọn agbaagba ati alẹnulọrọ ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo, ṣaaju eto idibo gomina to fẹẹ waye ninu oṣu Keji, ọdun 2027.

Mo Bimpe lérí láti gbé àwọn tó ní Lateef Adedimeji kọ́ ni bàbá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sílé ẹjọ́

Mo Bimpe lérí láti gbé àwọn tó ní Lateef Adedimeji kọ́ ni bàbá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sílé ẹjọ́

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 25 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 06:12:53

Lori ayelujara ni iroyin to ni Lateef Adedimeji kọ ni baba awọn Ibẹta ti n tan kalẹ

Fọ́nrán bí Abacha ṣe kú wà lọ́wọ́ mi, arúmọjẹ lásán ni ìtàn táwọn kan ń kọ sínú ìwé kiri - Al-Mustapha, olórí ẹ̀ṣọ́ aláàbò fún Abacha

Fọ́nrán bí Abacha ṣe kú wà lọ́wọ́ mi, arúmọjẹ lásán ni ìtàn táwọn kan ń kọ sínú ìwé kiri - Al-Mustapha, olórí ẹ̀ṣọ́ aláàbò fún Abacha

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 10:36:58

Latigba ti iku Ọgagun Abacha ti jade sita, ni ariyanjiyan ti wa kaakiri agbaye, paapaa nilẹ Naijiria to ti jẹ adari, ti awọn eeyan ko si gbagbe titi di asiko yii.

Kílódé tí àwọn èèyàn ń fi ohùn ránṣẹ́ sí Gheghe lórí ayélujára?

Kílódé tí àwọn èèyàn ń fi ohùn ránṣẹ́ sí Gheghe lórí ayélujára?

Ọjọ́ Àìkú, 26 Oṣù Agẹmọ 2026 ní 18:20:03

Gheghe gbajumọ fun awọn ọrọ to maa n sọ lori ayelujra fun awọn ọkunrin lori bi wọn ko sẹ gbọdọ maa na owo wọn fun obinrin.