world-service-rss

BBC News Yorùbá

Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o lè ta epo bẹntiróòlù fúnra rẹ láì nílò ìrànlọ́wọ́ ẹnikẹ́ni nílé epo? Ohun tí o ni láti ṣe rèé

Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o lè ta epo bẹntiróòlù fúnra rẹ láì nílò ìrànlọ́wọ́ ẹnikẹ́ni nílé epo? Ohun tí o ni láti ṣe rèé

Ọjọ́ Ẹtì, 11 Oṣù Owewe 2026 ní 14:25:21

Eto ti NNPC ṣẹṣẹ gbe kalẹ yii ti fawọn onibaara lanfaani lati ra epo sinu ọkọ tabi jẹrika funra wọn lai nilo iranwọ ẹnikẹni nile epo.

Akẹ́kọ̀ọ́ 24 jóná mọ́lé níléẹ̀kọ́ alákọ́bẹ̀rẹ̀, 21 míràn wà lẹ́sẹ̀-kan-ayé-ẹsẹ̀-kan-ọ̀run

Akẹ́kọ̀ọ́ 24 jóná mọ́lé níléẹ̀kọ́ alákọ́bẹ̀rẹ̀, 21 míràn wà lẹ́sẹ̀-kan-ayé-ẹsẹ̀-kan-ọ̀run

Ọjọ́ Ẹtì, 11 Oṣù Owewe 2026 ní 13:14:27

Ọmọdebinrin mọkandinlogun ati ọmọdekunrin marun un ni ina naa jo pa.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 11 Oṣù Owewe 2026 ní 13:29:21

Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́

‘Mi ò tíì fojú rí àwọn ọmọ mi fún ọdún mẹ́jọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìtòsí ara la wà’

'Mi ò tíì fojú rí àwọn ọmọ mi fún ọdún mẹ́jọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìtòsí ara la wà'

Ọjọ́ Ẹtì, 11 Oṣù Owewe 2026 ní 11:40:58

Ohun to n ba Ali lẹru bayii ni pe pẹlu bi ọrọ ṣe ri laarin igun mejeeji, afaimọ ko ma di eyi ti oun ko ni fi oju ri awọn ẹbi oun mọ layelaye.

Ṣé dátà 100mb yóò tó akẹ́kọ̀ọ́ láti kàwé lórí ayélujára lóòjọ́?

Ṣé dátà 100mb yóò tó akẹ́kọ̀ọ́ láti kàwé lórí ayélujára lóòjọ́?

Ọjọ́ Ẹtì, 11 Oṣù Owewe 2026 ní 10:38:24

Ijọba ni awọn akẹkọọ lati ile ẹkọ girama agba titi de fasti ni ọrọ naa yii kan.

Mo ti tẹ̀ fún Ọlọ́rùn, mi ò lè yẹ̀bá fún èèyàn mọ́, ẹ lọ fọkàn balẹ̀, mo máa dupò Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo lọ́dún 2027 – Oriyomi Hamzat

Mo ti tẹ̀ fún Ọlọ́rùn, mi ò lè yẹ̀bá fún èèyàn mọ́, ẹ lọ fọkàn balẹ̀, mo máa dupò Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo lọ́dún 2027 – Oriyomi Hamzat

Ọjọ́ Ẹtì, 11 Oṣù Owewe 2026 ní 06:38:23

Oriyomi toun ati Họnarebu Olakunle Busari tawọn eeyan mọ si Gudugudu jọ n sọ pe awọn mejeeji ni oludije sipo gomina fẹgbẹ oṣelu Accord nipinlẹ Oyo sọrọ yii ninu fọnran kan to fi lede lori ayelujara.

Àrùn diphtheria tó pa ọmọdé méje ní Imo ti rápálá wọ ìpínlẹ̀ Eko, wo bí o ṣe lè dáàbò bo ara rẹ

 Àrùn diphtheria tó pa ọmọdé méje ní Imo ti rápálá wọ ìpínlẹ̀ Eko, wo bí o ṣe lè dáàbò bo ara rẹ

Ọjọ́ Ẹtì, 11 Oṣù Owewe 2026 ní 08:31:59

Kọmiṣọna eto ilera, Akin Abayomi to fi ikede naa sita lọjọru sọ pe awọn ti n ṣetọju eeyan mẹfa to ko nigba awọn ti bẹrẹ si n wa awọn eeyan ti awọn eeyan naa ti farakan ṣaaju.

Ìpolongo ìbò Gómìnà bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ètò ìdìbò 2027, àmọ́, ìgbà wo ni Oriyomi àti Gudugudu yóò mọ ìpín wọn fẹ́gbẹ́ Accord l’Oyo?

Ìpolongo ìbò Gómìnà bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ètò ìdìbò 2027, àmọ́, ìgbà wo ni Oriyomi àti Gudugudu yóò mọ ìpín wọn fẹ́gbẹ́ Accord l'Oyo?

Ọjọ́bọ, 10 Oṣù Owewe 2026 ní 15:03:22

Oṣisẹ ajọ INEC kan to sọrọ ṣalaye wi pe edeaiyede to wa ninu ẹgbẹ oṣelu Acoord ni ko jẹ ki orukọ oludije sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu naa ko wa lara awọn orukọ awọn ti yoo dije dupo gomina ipinlẹ Oyo lati ẹgbẹ oṣelu naa.

Orí mi ni Garuba fẹ́ gé féú, ọwọ́ tí mo fi dáàbòbo ara mi, ló padà fi àdá ọwọ́ rẹ̀ gé – Adájọ́ tí olújẹ́jọ́ fi àdá gé lọ́wọ́ lásìkò ìgbẹ́jọ́ sọ̀rọ̀ síta

Orí mi ni Garuba fẹ́ gé féú, ọwọ́ tí mo fi dáàbòbo ara mi, ló padà fi àdá ọwọ́ rẹ̀ gé – Adájọ́ tí olújẹ́jọ́ fi àdá gé lọ́wọ́ lásìkò ìgbẹ́jọ́ sọ̀rọ̀ síta

Ọjọ́bọ, 10 Oṣù Owewe 2026 ní 13:31:26

Awọn eeyan to wa ninu yara igbẹjọ lo ka ọkunrin naa lọwọ ko, gba ada ọwọ rẹ ti wọn si gbe adajọ lọ sile iwosan fun itọju

Ṣé òótọ́ ni pé àgbo jẹ̀dí tí wọ́n fi ògógóró pò ló gbẹ̀mí ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn l’Ondo?

Ṣé òótọ́ ni pé àgbo jẹ̀dí tí wọ́n fi ògógóró pò ló gbẹ̀mí ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn l'Ondo?

Ọjọ́bọ, 10 Oṣù Owewe 2026 ní 12:28:29

Oniruru ilu ni iku naa ti waye ninu eyii ti Odigbo, Newtown ati Orita wa lara rẹ, to fi mọ Araromi-Obu.

APC fagilé ẹjọ́ tí wọ́n pè tako èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ́ Osun tó gbé Adeleke wọlé fún sáà kejì

APC fagilé ẹjọ́ tí wọ́n pè tako èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ́ Osun tó gbé Adeleke wọlé fún sáà kejì

Ọjọ́bọ, 10 Oṣù Owewe 2026 ní 11:51:43

Amofin Seyi Oyagbile lo pe ẹjọ naa lọjọ kẹjọ oṣù Kẹsán an yii lorukọ ẹgbẹ oṣelu APC ati lorukọ oludije ẹgbẹ naa, Bola Oyebamiji.

Kí ló dé tí iléeṣẹ́ ọmọogun fi gbé adarí ikọ̀ tó ń gbógun ti Boko Haram àtàwọn agbébọn kúrò pẹ̀lú àwọn ọ̀gágun 15 míràn? Ohun tí a mọ̀ rèé

Kí ló dé tí iléeṣẹ́ ọmọogun fi gbé adarí ikọ̀ tó ń gbógun ti Boko Haram àtàwọn agbébọn kúrò pẹ̀lú àwọn ọ̀gágun 15 míràn? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́bọ, 10 Oṣù Owewe 2026 ní 10:42:40

Awọn ti ọrọ naa kan lawọn ọgagun ti wọn wa nipo Major General ati Brigadier General.

Ìṣẹ́ alájótà, àtàwọn ohun tuntun míràn tí o kò mọ̀ nípa Temitope Osoba, gbajúmọ̀ òṣèré tí wọ́n ń sin òkú rẹ̀ lónìí

Ìṣẹ́ alájótà, àtàwọn ohun tuntun míràn tí o kò mọ̀ nípa Temitope Osoba, gbajúmọ̀ òṣèré tí wọ́n ń sin òkú rẹ̀ lónìí

Ọjọ́bọ, 10 Oṣù Owewe 2026 ní 08:52:36

Ṣaaju iṣẹ tiata, tipẹtipẹ ko too bẹrẹ sii farahan ninu awọn ere agbelewo, lo ti n ṣiṣẹ alajota, to si tun n jo ninu awọn awo orin loriṣiriṣi.

Kò sí orúkọ Oriyomi Hamzat tàbí Gudugudu gẹ́gẹ́bí olùdíje sípò Gómìnà fẹ́gbẹ́ Accord nínú àkọsílẹ̀ INEC ní ìpínlẹ̀ Oyo - Ìwádìí BBC

Kò sí orúkọ Oriyomi Hamzat tàbí Gudugudu gẹ́gẹ́bí olùdíje sípò Gómìnà fẹ́gbẹ́ Accord nínú àkọsílẹ̀ INEC ní ìpínlẹ̀ Oyo - Ìwádìí BBC

Ọjọ́bọ, 10 Oṣù Owewe 2026 ní 07:09:09

Iwadii BBC News Yoruba si ọfiisi ajọ eleto idibo INEC ẹka ipinlẹ Oyo fi han wi pe ko si orukọ oludije sipo gomina lati inu ẹgbẹ oṣelu Accord kankan ninu orukọ awọn oludije sipo gomina to wa ninu akọsilẹ INEC fun eto idibo ọdun 2027.

Ó tó gẹ́! A ò fẹ́ kí Sẹ́nẹ́tọ̀ Francis Fadahunsi ṣojú wa mọ́ nílé aṣòfin àgbà l’Abuja, - Àwọn Ọ̀dọ́ Ilẹ̀ Ijesa yari

Ó tó gẹ́! A ò fẹ́ kí Sẹ́nẹ́tọ̀ Francis Fadahunsi ṣojú wa mọ́ nílé aṣòfin àgbà l'Abuja, - Àwọn Ọ̀dọ́ Ilẹ̀ Ijesa yari

Ọjọ́rú, 9 Oṣù Owewe 2026 ní 15:27:09

Ṣaaju eto idibo gomina ipinlẹ Ọsun to waye loṣu to kọja ni Sẹnẹtọ n to soju Ifẹ Ijẹsa nile igbimọ aṣofin agba l’Abuja naa ti sọrọ kan to gba ori ayelujara pe ki wọn maa pa gbogbo ọmọ ẹgbẹ oṣelu Accord ti i ṣe ẹgbẹ Gomina Ademola Adeleke, tabi ẹnikẹni to ba ti de fila ẹgbẹ oṣelu naa.

‘Ẹ̀yin nìkan kọ́ ló ń kojú ìṣòro iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì’ - Ààrẹ Adama Barrow sọ̀rọ̀ lórí ìwọ́de ìdákúrekú iná tó ń wáyé ní Gambia

'Ẹ̀yin nìkan kọ́ ló ń kojú ìṣòro iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì' - Ààrẹ Adama Barrow sọ̀rọ̀ lórí ìwọ́de ìdákúrekú iná tó ń wáyé ní Gambia

Ọjọ́rú, 9 Oṣù Owewe 2026 ní 13:34:24

Awọn eeyan lorilẹede Gambia n ṣe iwọde nitori idakureku ina ọba to n ṣẹlẹ lorilẹede naa lati oṣu kẹfa.

Mo pinnu láti fi Ogogo ṣe olùbádámọ̀ràn pàtàkì nínú ìjọba mi tí mo bá di gómìnà – Yayi

Mo pinnu láti fi Ogogo ṣe olùbádámọ̀ràn pàtàkì nínú ìjọba mi tí mo bá di gómìnà – Yayi

Ọjọ́rú, 9 Oṣù Owewe 2026 ní 11:17:13

Yayi lo sọrọ yii lasiko to ṣabẹwo ibanikẹdun si mọlẹbi Ogogo niluu Ilaro.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

‘Aago meji oru ni mo dele; ọ́fíìsì ni màá sùn lọjọru’ - aráàlú kojú ìnira, ìdádúró ọ̀pọ̀ wákàtí lópópónà Eko sí Ibadan nítorí àtúnṣe afárá Kara, ìgbà tí yóò parí

'Aago meji oru ni mo dele; ọ́fíìsì ni màá sùn lọjọru' - aráàlú kojú ìnira, ìdádúró ọ̀pọ̀ wákàtí lópópónà Eko sí Ibadan nítorí àtúnṣe afárá Kara, ìgbà tí yóò parí

Ọjọ́rú, 9 Oṣù Owewe 2026 ní 10:14:31

Akọroyin BBC to gba oju ọhun jabọ pe sunkẹrẹ-fakẹrẹ naa bẹrẹ lati ọsan, o si gun lati afara Kara nipinlẹ Ogun titi de agbegbe 7Up niluu Eko.

Wo bí ètò ìsínkú gbajúmọ̀ òṣèré tíátà, Temitope Osoba tó jáde láyé láìpẹ́ yìí yóò ṣe lọ

Wo bí ètò ìsínkú gbajúmọ̀ òṣèré tíátà, Temitope Osoba tó jáde láyé láìpẹ́ yìí yóò ṣe lọ

Ọjọ́rú, 9 Oṣù Owewe 2026 ní 08:03:15

Titi di asiko yii ni awọn oṣere tiata, to fi mọ awọn ololufẹ ere tiata nilẹ Naijiria ati kaakiri agbaye ṣi n kẹdun iku obinrin naa, ti wọn si n sọ pe awọn yoo ṣafẹri rẹ, paapaa lori awọn igbesẹ akikanju to gbe nigba aye rẹ.

Kí ló tún wú ọ̀rọ̀ àkọsílẹ̀ Tinubu pẹ̀lú ọlọ́pàá FBI Amẹrika nípà egbòogi olóró síta? Àlàyé rèé

Kí ló tún wú ọ̀rọ̀ àkọsílẹ̀ Tinubu pẹ̀lú ọlọ́pàá FBI Amẹrika nípà egbòogi olóró síta? Àlàyé rèé

Ọjọ́rú, 9 Oṣù Owewe 2026 ní 06:28:01

Ọpọ eeyan papaa julọ awọn ẹgbẹ oṣelu alatako ni Naijiria lo beere wi pe ki Amẹrika gbe akọsilẹ igbẹjọ Tinubu lori ọrọ egboogi oloro jade.

Kí ni èrè rẹ nínú ilẹeṣẹ ìfọpo Dangote bayìí tí iléeṣẹ́ náà yóò bẹ̀rẹ̀ sí ń ta ìpín rẹ̀? Àlàyé rèé

Kí ni èrè rẹ nínú ilẹeṣẹ ìfọpo Dangote bayìí tí iléeṣẹ́ náà yóò bẹ̀rẹ̀ sí ń ta ìpín rẹ̀? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 8 Oṣù Owewe 2026 ní 15:56:58

Dangote sọ pe iye to kere julọ ti eeyan kan le ra ninu ipin naa ni mẹwaa pere, ti iye rẹ jẹ N5,250.

Ṣé lóòótọ́ ni wọ́n lẹ òkò mọ́ Peter Obi ní Benue? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ṣé lóòótọ́ ni wọ́n lẹ òkò mọ́ Peter Obi ní Benue? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 8 Oṣù Owewe 2026 ní 16:12:16

Peter Obi lo lọ si ipinlẹ Benue pẹlu erongba lati kẹdun ikọlu to waye lagbegbe Yelwata laipẹ yii, nibi ti ọpọ eeyan ti ba ikọlu naa lọ sọrun aremabọ, ti ọpọ si farapa.

'’Ọmọ mi mẹ́ta ni mo tà, N300,000 ni mo ta ìbejì mi, ṣọ́ọ̀bù tí mo ti ń tàgbo tó jóná ló sọ mí di gbọ́mọ-gbọ́mọ’’

''Ọmọ mi mẹ́ta ni mo tà, N300,000 ni mo ta ìbejì mi, ṣọ́ọ̀bù tí mo ti ń tàgbo tó jóná ló sọ mí di gbọ́mọ-gbọ́mọ''

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 8 Oṣù Owewe 2026 ní 06:32:13

Afurasi gbọmọ-gbọmọ naa sọ pe obinrin kan tawọn jọ ṣiṣẹ pọ lọja Ogeere lo kọ oun bi eeyan ṣe maa n ji ọmọ gbe.

APC sẹ́, PDP sẹ́, ta ló wá pe ẹjọ́ tako gómìnà Adeleke níléẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹ̀hónú ìdìbò gómìnà l’Osun?

APC sẹ́, PDP sẹ́, ta ló wá pe ẹjọ́ tako gómìnà Adeleke níléẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹ̀hónú ìdìbò gómìnà l'Osun?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 8 Oṣù Owewe 2026 ní 14:01:44

Akọroyin BBC Yoruba to lọ si ọọfisi igbimọ naa, to si fi oju gaani iwe ipẹjọ ọhun fidi rẹ mulẹ pe APC ati PDP lo pe ẹjọ naa.

Kí ló dé tí àwọn ẹ̀yà Tigray ní Ethiopia ṣe ń sọ pé àgbà Olóyè Obasanjo kò tolé?

Kí ló dé tí àwọn ẹ̀yà Tigray ní Ethiopia ṣe ń sọ pé àgbà Olóyè Obasanjo kò tolé?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 8 Oṣù Owewe 2026 ní 11:10:48

Ẹgbẹ ajijagbara TPLF fẹsun kan Ọbasanjọ pe o n ṣegbe lẹyin igun kan.

Kí ló ṣokùnfà ikú gbajúmọ̀ òṣèrèbìnrin, Nimmy Ferrari tó jáde láyé lásìkò tó ń palẹ̀mọ́ láti ṣí ilé tuntun tó kọ́?

Kí ló ṣokùnfà ikú gbajúmọ̀ òṣèrèbìnrin, Nimmy Ferrari tó jáde láyé lásìkò tó ń palẹ̀mọ́ láti ṣí ilé tuntun tó kọ́?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 8 Oṣù Owewe 2026 ní 10:14:37

Ọkan lara awọn oṣerebinrin nni, Oluwakemisola Apesin, ẹni tọpọ mọ si Anti Sidi lo tufọ iku oloogbe naa lori ikanni ayelujara.

Ṣé lóòótọ́ ni Tinubu buwọ́lù ẹ̀wọ̀n gbére fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó bá kùnà láti dá owóòyá NELFUND padà fún ìjọba? Àlàyé rèé

Ṣé lóòótọ́ ni Tinubu buwọ́lù ẹ̀wọ̀n gbére fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó bá kùnà láti dá owóòyá NELFUND padà fún ìjọba? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Ajé, 7 Oṣù Owewe 2026 ní 14:11:35

Lọdun 2024 ni Tinubu buwọlu ofin idasilẹ ajọ NELFUND to n ri si eto owooya fawọn akẹkọọ ti ko rọwọ họri lawọn ile ẹkọ giga ni Naijiria.

Sẹ́nétọ̀ Buba sọ̀rọ̀ lórí fídíò tó gba orí ayélujára pé ó ṣàtìlẹyìn fáwọn agbébọn

Sẹ́nétọ̀ Buba sọ̀rọ̀ lórí fídíò tó gba orí ayélujára pé ó ṣàtìlẹyìn fáwọn agbébọn

Ọjọ́ Ajé, 7 Oṣù Owewe 2026 ní 15:43:12

Ninu fidio naa ni Hassan ti fẹsun kan pe niṣe ni Sẹnetọ naa n idanilẹkọọ fawọn agbebọn to pe orukọ wọn ni Babangida ati Lema.

Bàlúù yà wọ ojú pópó, kọlu ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkọ́, ẹ̀mí márùn ún lọ síi, ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lọ́gán

Bàlúù yà wọ ojú pópó, kọlu ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkọ́, ẹ̀mí márùn ún lọ síi, ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lọ́gán

Ọjọ́ Ajé, 7 Oṣù Owewe 2026 ní 12:12:03

Pupọ awọn to farapa naa lo jẹ pe wọn ha mọ inu tabi abẹ ọkọ ni to si jẹ pe awọn panapana ni lati sa ipa kikankikan ki wọn to le yọ wọn.

Ǹjẹ́ o mọ̀ pé àwọn èèyàn kan wà tí wọn kò ní ilà ọwọ́? Ohun tó fà á ree

Ǹjẹ́ o mọ̀ pé àwọn èèyàn kan wà tí wọn kò ní ilà ọwọ́? Ohun tó fà á ree

Ọjọ́ Àìkú, 6 Oṣù Owewe 2026 ní 08:26:09

Aini ila ọwọ tabi tẹsẹ ti oloyinbo n pe ni adermatoglyphia jẹ nnkan ti wọn maa n bi mọ eeyan, amọ, iru rẹ ko wọpọ rara.

Mo fẹ lọ fún ìsinmi díẹ̀ kí ara lè tù mí láti lé sin àwọn èèyàn Osun dáadáa - Gómìnà Adeleke

Mo fẹ lọ fún ìsinmi díẹ̀ kí ara lè tù mí láti lé sin àwọn èèyàn Osun dáadáa - Gómìnà Adeleke

Ọjọ́ Ajé, 7 Oṣù Owewe 2026 ní 11:39:51

Irinajo isinmi naa n waye lẹyin ọsẹ mẹta ti Adeleke bori eto idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Ọṣun.

‘Mo wá sí Naijiria láti kojú ọmọ Yahoo tó fẹ́ lu ìyá mi ni jìbìtì àmọ́ ohun tí mo bábọ̀ rèé’

'Mo wá sí Naijiria láti kojú ọmọ Yahoo tó fẹ́ lu ìyá mi ni jìbìtì àmọ́ ohun tí mo bábọ̀ rèé'

Ọjọ́ Àìkú, 6 Oṣù Owewe 2026 ní 10:25:12

Nọmba idanimọ ori foonu rẹ ṣafihan pe Naijiria lo ti n fi awọn atẹjiṣẹ ranṣẹ sori foonu iya Carlos lodi si Syria to ni oun wa gẹgẹ ọmọ ogun ilẹ Amẹrika to ni oun jẹ.

Wo àwọn alága EFCC tẹ́lẹ̀rí tí wọ́n ti fẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ kàn

Wo àwọn alága EFCC tẹ́lẹ̀rí tí wọ́n ti fẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ kàn

Ọjọ́ Àìkú, 6 Oṣù Owewe 2026 ní 11:48:16

Alaga ajọ EFCC tẹlẹri, Abdulrasheed Bawa, dero atimọle ajọ ọtẹmulẹyẹ DSS lọdun 2023 lori ẹsun ṣiṣe ṣowo ilu kumọ kumọ, ṣiṣi ipo lo ati didari owo dukia ijọba ti EFCC ta si ibomiran.

Ẹ yàgò fún òṣèlú kí epo má baà ta sí àlà yín, Makinde kìlọ̀ fún àwọn Ọba Oyo

Ẹ yàgò fún òṣèlú kí epo má baà ta sí àlà yín, Makinde kìlọ̀ fún àwọn Ọba Oyo

Ọjọ́ Àìkú, 6 Oṣù Owewe 2026 ní 11:36:37

Gomina naa tun ke si awọn ori ade ki wọn tẹsiwaju lati maa gbe ni alaafia pẹlu awọn ti wọn jẹ ọba le lori.

Kí ló ṣokùnfà ikú ọmọ ìyá mẹ́ta lọ́jọ́ kan náà l’Ondo? Ohun tí a mọ̀ rèé

Kí ló ṣokùnfà ikú ọmọ ìyá mẹ́ta  lọ́jọ́ kan náà l'Ondo? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́ Ajé, 7 Oṣù Owewe 2026 ní 06:35:13

Ẹkun sọ lẹyin ti wọn ri oku awọn mẹtẹẹta ninu odo kekere kan, lẹyin ti wọn ti n wa wọn kiri.

Ṣé òótọ́ ni pé àwọn Kristẹni nìkan làwọn jàndùkú agbébọn ń kọlù ní Naijiria?

Ṣé òótọ́ ni pé àwọn Kristẹni nìkan làwọn jàndùkú agbébọn ń kọlù ní Naijiria?

Ọjọ́bọ, 3 Oṣù Owewe 2026 ní 08:55:23

Bo tilẹ jẹ pe ijọba Naijiria n gbiyanju lati koju irufẹ ikọlu ọhun, ikọlu awọn agbebọn ti di lemọlemọ ni Naijria.

Ilé aṣojú-ṣòfin rí àpò àṣùwọ̀n owó 58 tó so mọ́ Adeniyi Adeyemi, bó ṣe wẹ Gbajabiamila mọ́ pé kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ayédèru iléeṣẹ́ PFIPC

Ilé aṣojú-ṣòfin rí àpò àṣùwọ̀n owó 58 tó so mọ́ Adeniyi Adeyemi, bó ṣe wẹ Gbajabiamila mọ́ pé kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ayédèru iléeṣẹ́ PFIPC

Ọjọ́bọ, 3 Oṣù Owewe 2026 ní 12:45:51

Bakan naa ni wọn fidi rẹ mulẹ pe Gbajabiamila lo n ṣiṣẹ tako idasilẹ awọn ayederu ileeṣẹ yii, ti aṣiri rẹ fi tu sita fun gbogbo araye.

Sunday Igboho sọ̀rọ̀, orí ayélujára tún gbóná jain-jain, áláyé rèé

Sunday Igboho sọ̀rọ̀, orí ayélujára tún gbóná jain-jain, áláyé rèé

Ọjọ́ Ẹtì, 4 Oṣù Owewe 2026 ní 06:01:58

Ninu fidio kan to gba ori ayelujara ni Igboho ti n sọ fun awọn ẹṣọ aabo naa pe agbebọn ti wọn ba ti ba ibọn lọwọ rẹ ninu igbo ni ki wọn pa lẹyẹ o sọka.

Àlàyé rèé lórí bí a ṣe ṣàwárí, dóòlà àwọn tí ajínigbé gbé ní Oriire, ọ̀nà táwọn èèyàn mẹ́sàn-án gbà kú àti ọ̀pọ̀ òfegè ìròyìn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà - Ọ̀gá DSS

Àlàyé rèé lórí bí a ṣe ṣàwárí, dóòlà àwọn tí ajínigbé gbé ní Oriire, ọ̀nà táwọn èèyàn mẹ́sàn-án gbà kú àti ọ̀pọ̀ òfegè ìròyìn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà - Ọ̀gá DSS

Ọjọ́ Ẹtì, 4 Oṣù Owewe 2026 ní 07:59:12

Awọn ti ko din ni mẹrindinlaadọta, olukọ meje ati akẹkọọ mọkandinlogoji ni awọn janduku agbebọn naa jigbe wọnu igbo lọ.

Àṣírí ibi tí wọ́n ti n ṣe ayédèrú owó Euro tú n’ibadan, àwọn afurasí há

Àṣírí ibi tí wọ́n ti n ṣe ayédèrú owó Euro tú n'ibadan, àwọn afurasí há

Ọjọ́ Ẹtì, 4 Oṣù Owewe 2026 ní 10:50:51

Ẹgbẹrun mẹjọ ati ẹẹdẹgbẹrun owo Euro ti gbogbo rẹ ayederu ni ọlọpaa sọ pe awọn gba lọwọ awọn afurasi naa.

Báyìí ni ìgbẹ́jọ́ awakọ̀ Anthony Joshua tún ṣe lọ àti àwọn kókó ẹ̀sùn mẹ́rin tí olùpẹ́jọ́ gbé kalẹ̀

Báyìí ni ìgbẹ́jọ́ awakọ̀ Anthony Joshua tún ṣe lọ àti àwọn kókó ẹ̀sùn mẹ́rin tí olùpẹ́jọ́ gbé kalẹ̀

Ọjọ́ Ẹtì, 4 Oṣù Owewe 2026 ní 11:18:46

Wọn sọ fun ile ẹjọ pe niṣe ni Joshua atawọn ọrẹ rẹ ti sun lọ ninu ọko Lexus SUV ti wọn wa nigba ti wọn n lọ si ilu Sagamu ki ijamba naa to waye.

Kí ló fá ikú ọ̀pọ̀ èèyàn tó ń jí epo rọ̀bì fà ní Okrika, ìpínlẹ̀ Rivers? Ohun tí a mọ̀

Kí ló fá ikú ọ̀pọ̀ èèyàn tó ń jí epo rọ̀bì fà ní Okrika, ìpínlẹ̀ Rivers? Ohun tí a mọ̀

Ọjọ́ Ẹtì, 4 Oṣù Owewe 2026 ní 10:19:28

Nnkan bi agogo mejila ori, Ọjọbọ, ọsẹ yii, ọjọ kẹta, oṣu Kẹsan, ọdun 2026 ni iṣẹlẹ naa waye ni adugbo Okari Jetty, iyẹn lagbegbe Okrika Mainland.

Àṣírí gbọ́mọgbọ́mọ méjì tó ń wọ Hijab láì ṣe Mùsùlùmí tú lásìkò tí wọn tún fẹ́ jí ọmọ míì gbé

Àṣírí gbọ́mọgbọ́mọ méjì tó ń wọ Hijab láì ṣe Mùsùlùmí tú lásìkò tí wọn tún fẹ́ jí ọmọ míì gbé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 5 Oṣù Owewe 2026 ní 06:06:59

Eyi lo n waye lẹyin ọjọ diẹ tawọn ẹṣọ aabo n kọminu lori bi ijinigbe awọn ọmọde ṣe n waye lemọlemọ lẹnu ọjọ mẹta yii ni ilu Abuja atawọn agbegbe mii ni Naijiria.