world-service-rss

BBC News Yorùbá

Kí ló wà nínú àdéhùn àlááfíà tí Ààrẹ Tinubu àtàwọn ẹgbẹ́ òṣèlú tọwọ́ bọ̀ bí ìpolongo ìbò ṣe bẹ̀rẹ̀?

Kí ló wà nínú àdéhùn àlááfíà tí Ààrẹ Tinubu àtàwọn ẹgbẹ́ òṣèlú tọwọ́ bọ̀ bí ìpolongo ìbò ṣe bẹ̀rẹ̀?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 22 Oṣù Ògún 2026 ní 10:50:43

Atẹjade ti INEC fi sita lori ipolongo ibo ọdun to n bọ naa ṣalaye pe, awọn ẹgbẹ oṣelu le bẹrẹ ipolongo bayii.

Kí ló lè fa kí òkúta rìgìdì tó tóbi tó ọmọ ìkókó wà nínú àpò ilé ìtọ̀ ọkunrin?Àlàyé rèé

Kí ló lè fa kí òkúta rìgìdì tó tóbi tó ọmọ ìkókó wà nínú àpò ilé ìtọ̀ ọkunrin?Àlàyé rèé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 22 Oṣù Ògún 2026 ní 10:31:35

Awọn okuta ninu apo itọ yii maa n parapọ di odidi nigba ti awọn eroja kan ninu itọ ba dipọ, ti wọn di koko.

Wo àwọn ohun tó ṣẹlẹ̀ nígbà táwọn àgbà òṣèré tíátá wọlé àdúrà fún Taiwo Hassan Ogogo lórí àìsàn Jẹjẹrẹ

Wo àwọn ohun tó ṣẹlẹ̀ nígbà táwọn àgbà òṣèré tíátá wọlé àdúrà fún Taiwo Hassan Ogogo lórí àìsàn Jẹjẹrẹ

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 22 Oṣù Ògún 2026 ní 10:13:08

Inu gbọngan Babajide Olushola Sanwo-Olu ti ileeṣẹ amohunmaworan tipinlẹ Eko, LTV 8 to wa lagbegbe Agidingbi ni eto adura ọhun ti waye, lati fi ifẹ han si ọsere naa.

Kí ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ Ilẹ riri tó pa ọ̀pọ̀ eeyan to le ni ọgọ́rùn-ún

Kí ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ Ilẹ riri tó pa ọ̀pọ̀ eeyan to le ni ọgọ́rùn-ún

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 22 Oṣù Ògún 2026 ní 10:07:18

Agbegbe ti wọn ti n wa kusa ni iṣẹlẹ aburu ọhun ti waye, nigba ti wọn sọ pe ojiji ni ilẹ bẹrẹ sii ri mọ awọn eeyan lẹsẹ.

Afẹnifere figbeta pé àfikún ti ba ìjínigbé, ìpànìyàn àti ìkọlù tó ń kojú àwọn àgbẹ̀ ilẹ̀ Yorùbá

Afẹnifere figbeta pé àfikún ti ba ìjínigbé, ìpànìyàn àti ìkọlù tó ń kojú àwọn àgbẹ̀ ilẹ̀ Yorùbá

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 22 Oṣù Ògún 2026 ní 06:58:18

Afẹnifẹrẹ sọ pe ikọlu ti ko figba kan duro tẹlẹ ti wa n le si i lori awọn agbẹ bayii

Wo àwọn ohun tó yẹ kó o mọ̀ nípa Victoria Oluwakotanmi, ọmọ Naijiria-America tó gba adé Omidan ‘Grand USA 2026’

Wo àwọn ohun tó yẹ kó o mọ̀ nípa Victoria Oluwakotanmi, ọmọ Naijiria-America tó gba adé Omidan 'Grand USA 2026'

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 15:51:27

Oluwakotanmi ni yoo gbe ade America yii lọ ṣoju orilẹede naa nibi idije Miss Grand International.

Wo àwọn ìpínlẹ̀ mọ́kànlá ní Nàìjíríà tí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì kìlọ̀ pé ó léwu fáwọn èèyàn rẹ láti lọ

Wo àwọn ìpínlẹ̀ mọ́kànlá ní Nàìjíríà tí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì kìlọ̀ pé ó léwu fáwọn èèyàn rẹ láti lọ

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 12:22:15

UK tún kìlọ̀ fáwọn eeyan láti ṣọra fun awọn agbegbe miran to fi mọ olu ilu ilẹ Naijiria.

Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan

Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 10:11:03

Ogun marundinlaadọjọ ni itan sọ pe Balogun Oderinlo ja nigba to wa laye, to si bori rẹ, ko to di pe o fi aye silẹ lọdun 1850

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 13:17:49

Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́

Ọkọ̀ ojú omi tó kó èrò 77 yí dànù, èrò 46, tí ọ̀pọ̀ wọn jẹ́ ọmọdé kú, 15 yè, wọn ń wá àwọn èèyàn 16 tó kù

Ọkọ̀ ojú omi tó kó èrò 77 yí dànù, èrò 46, tí ọ̀pọ̀ wọn jẹ́ ọmọdé kú, 15 yè, wọn ń wá àwọn èèyàn 16 tó kù

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 09:06:41

Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Sokoto fisita salaye pe eeyan mẹtadinlọgọrin lo wa ninu ọkọ oju omi naa.

Àlàyé rèé lórí ohun tí Ademola Adeleke lọ ṣe lọ́dọ Tinubu àti Wike ní Abuja

Àlàyé rèé lórí ohun tí Ademola Adeleke lọ ṣe lọ́dọ Tinubu àti Wike ní  Abuja

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 06:28:10

Deedee agogo marun-un kọja iṣẹju marundinlọgbọn irọlẹ ni Adeleke wọnu ọgba Aso Rock na pẹlu ọkọ ayọkẹlẹ Toyota Land Cruiser SUV rẹ.

Ọdún kan sẹ́yìn ni mo ti ń ṣàìsàn, dókítà kò sì mọ ohun tó ń ṣe mí - Opebe onítíátà

Ọdún kan sẹ́yìn ni mo ti ń ṣàìsàn, dókítà kò sì mọ ohun tó ń ṣe mí - Opebe onítíátà

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 05:08:24

Ọjọ Iṣẹgun, ọsẹ yii ni Kunle Afod gbe fọnran ifọrọwerọ to ṣe pẹlu Ọpẹbẹ soju opo Youtube rẹ, to si n ṣe awọn eeyan ni kayeefi.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu òfin gbogbo ogúnjọ́ oṣù Kẹ́jọ bíi àyájọ́ Ìṣẹ̀ṣe láì yẹ̀

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu òfin gbogbo ogúnjọ́ oṣù Kẹ́jọ bíi àyájọ́ Ìṣẹ̀ṣe láì yẹ̀

Ọjọ́bọ, 20 Oṣù Ògún 2026 ní 16:21:26

Kọmiṣanaa fun eto Igbafẹ ati Aṣa nipinlẹ Oyo, Wasiu Olatunbosun, lo fidi eyi mulẹ fawọn akọroyin nibi ayẹyẹ naa to waye ni papa iṣere Adamasingba, niluu Ibadan.

Wo gbèdéke owó tí òfin là kalẹ̀ fún olùdíje sípò ààrẹ, gómìnà àtàwọn olùdíje míì láti ná fún ìpolongo ìbò 2027

Wo gbèdéke owó tí òfin là kalẹ̀ fún olùdíje sípò ààrẹ, gómìnà àtàwọn olùdíje míì láti ná fún ìpolongo ìbò 2027

Ọjọ́bọ, 20 Oṣù Ògún 2026 ní 12:01:36

Apapọ owo ti oludije kọọkan yoo na, lo lọ ni ibamu pẹlu iwe ofin eto idibo ti ọdun 2026 ti wọn ṣe atungbeyẹwo rẹ.

Wo ohun mẹ́jọ pàtàkì nípa ọdún Iṣẹ̀ṣe nílẹ̀ Yorùbá tí ìjọba Oyo, Ogun àti Eko fi kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́

Wo ohun mẹ́jọ pàtàkì nípa ọdún Iṣẹ̀ṣe nílẹ̀ Yorùbá tí ìjọba Oyo, Ogun àti Eko fi kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́

Ọjọ́bọ, 20 Oṣù Ògún 2026 ní 09:25:25

Lara awọn ipinlẹ to ti buwọ lu ayajọ naa fawọn oniṣẹṣe naa la ti ri ipinlẹ Ogun, Eko ati Oyo, ti awọn ijọba naa si tun n kede olude fun gbogbo oṣiṣẹ patapata.

Ìjàmbá ọkọ̀ ló sọ mí di ẹlẹ́sẹ̀ kan, ìdí eré ìdárayá Onídà ni mo ti ń gbọ́ bùkátà ọmọ méjì - Aanu Kumuyi

Ìjàmbá ọkọ̀ ló sọ mí di ẹlẹ́sẹ̀ kan, ìdí eré ìdárayá Onídà ni mo ti ń gbọ́ bùkátà ọmọ méjì - Aanu Kumuyi

Ọjọ́bọ, 20 Oṣù Ògún 2026 ní 11:24:16

BBC News Yorùbá bá obìnrin àkàndá ẹ̀dá kan, tó ń kópa nínú eré ìdárayá Onídà, tí à mọ̀ sí Fencing sọ̀rọ̀ láti mọ̀ nípa eré ìdárayà náà àti ìpèníjà rẹ̀.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 21 Oṣù Ògún 2026 ní 13:17:49

Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́

Kí ló fa ìró ìbọn tó dún lákọlákọ nígboro Osogbo tí ẹ̀mí kan fi bọ́, báwo ló ṣe kan gómìnà Adeleke àti Davido? Àlàyé rèé

Kí ló fa ìró ìbọn tó dún lákọlákọ nígboro Osogbo tí ẹ̀mí kan fi bọ́, báwo ló ṣe kan gómìnà Adeleke àti Davido? Àlàyé rèé

Ọjọ́bọ, 20 Oṣù Ògún 2026 ní 09:57:45

Ojelabi sọ pe ọsan ọjọ naa ni Gomina Ademola Adeleke ati aburo rẹ to jẹ gbajugbaja olorin takasufee, David Adeleke tọpọ mọ si Davido ṣabẹwo si aafin Ata-Oja tiluu Osogbo, Ọba Jimoh Olanipekun lasiko ti isẹlẹ naa waye.

Ìdí rèé tí a kò fi lè gbé Ogogo lọ fún ìtọ́jú lọ́dọ̀ èèyàn tó lé ní 500 tó fẹ́ tọ́jú rẹ̀ - Jide Kosoko, Yinka Quadri

Ìdí rèé tí a kò fi lè gbé Ogogo lọ fún ìtọ́jú lọ́dọ̀ èèyàn tó lé ní 500 tó fẹ́ tọ́jú rẹ̀ - Jide Kosoko, Yinka Quadri

Ọjọ́bọ, 20 Oṣù Ògún 2026 ní 06:19:52

Ohun kan ti Oloye Jide Kosoko tun yannana rẹ ninu atẹjade rẹ ni pe kawọn eeyan ma ṣe binu bawọn ko ba le gbe Ogogo wa sọdọ wọn fun itọju.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Àkójọpọ̀ ìròyìn bó ṣe ń lọ nínú ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Àkójọpọ̀ ìròyìn bó ṣe ń lọ nínú ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

__

Ìròyìn àtìgbàdégbà nípa ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Adeleke fìdí Oyebamiji àti Salaam janlẹ̀, ó borí ìbò fún sáà kejì

Adeleke fìdí Oyebamiji àti Salaam janlẹ̀, ó borí ìbò fún sáà kejì

Ọjọ́ Àìkú, 16 Oṣù Ògún 2026 ní 07:21:18

Bi idibo ṣe waye naa ni kika rẹ ti gbera sọ lawọn ibi kan l’Osun

Kókó ohun mẹ́fà nípa Ademola Adeleke, gómìnà ìpínlẹ̀ Osun tó wọlé ṣáá kejì

Kókó ohun mẹ́fà nípa Ademola Adeleke, gómìnà ìpínlẹ̀ Osun tó wọlé ṣáá kejì

Ọjọ́ Àìkú, 16 Oṣù Ògún 2026 ní 07:10:02

Fasiti Jacksonville State to wa niluu Alabama ni Adeleke lọ nilẹ Amẹrika, nibi to ti kẹkọọ nipa ẹkọ nipa eto oṣelu.

Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi àyájọ́ ọdún Sango àgbáyé tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Oyo

Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi àyájọ́ ọdún Sango àgbáyé tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Oyo

Ọjọ́ Àìkú, 16 Oṣù Ògún 2026 ní 07:48:25

Ọpọ awọn aṣoju aṣa kaakiri agbaye bii Paulo Santos lati orileede Portugal, ati Felix Coastales lati orileede Spain ni wọn peju sibi eto ayẹyẹ ọdun Sango naa, to wọn si gbe oriyin fun Alaafin Oyo lori ipa ati akitiyan rẹ nipa gbigbe aṣa ati iṣẹṣe larugẹ.

Russia ṣekúpa èèyàn mẹ́jọ ní Ukraine, àwọn mọ́kàndínlógójì farapa

Russia ṣekúpa èèyàn mẹ́jọ ní Ukraine, àwọn mọ́kàndínlógójì farapa

Ọjọ́ Àìkú, 16 Oṣù Ògún 2026 ní 13:13:17

Awọn alakoso ilẹ Russia ti wa fidi rẹ mulẹ agbegbe ti ado oloro naa ti dun, ni wọn ti n ṣe awọn eroja ohun elo oju ogun loriṣiriṣi.

‘Bí àwọn èèyàn bá rí mi, ọmọ gómìnà Adeleke ni wọ́n ń pè mí nítorí pé a jọra gidigidi’

'Bí àwọn èèyàn bá rí mi, ọmọ gómìnà Adeleke ni wọ́n ń pè mí nítorí pé a jọra gidigidi'

Ọjọ́ Àìkú, 16 Oṣù Ògún 2026 ní 15:19:07

Ọgbẹni Oluwaseyi Afonriwo jẹ ẹni ti ọpọ ti tọka si pe o jọ gomina Adeleke bi imumu.

Kókó ọ̀rọ̀ tí Ẹrọ Arike sọ léyìn tí olùdíje APC lulẹ̀ nínú ètò ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Kókó ọ̀rọ̀ tí Ẹrọ Arike sọ léyìn tí olùdíje APC lulẹ̀ nínú ètò ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun

Ọjọ́ Àìkú, 16 Oṣù Ògún 2026 ní 14:53:30

Ero Arike rọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC lati fọwọ wọnu ki wọn si ṣe ọkan akin tori bi ọrọ ibo ṣe maa n ri nigba mii niyẹn.

APC Osun sọ̀rọ̀ sókè lórí ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn tó lulẹ̀ nínú ìbò gómìnà

APC Osun sọ̀rọ̀ sókè lórí ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn tó lulẹ̀ nínú ìbò gómìnà

Ọjọ́ Ajé, 17 Oṣù Ògún 2026 ní 08:30:14

APC ni kaakiri gbogbo wọọdu ojilelọgbọnlelọọdunrun (332) ti eto idibo ti waye lawọn yoo ṣagbeyẹwo finnifinni ko to di pe awọn mọ igbese to kan.

Àwọn wo ni ẹbí Adeleke tó dí ètò òṣèlú mú ṣinṣin l’Osun lati ọdun 1979?

Àwọn wo ni ẹbí Adeleke tó dí ètò òṣèlú mú ṣinṣin l'Osun lati ọdun 1979?

Ọjọ́ Ajé, 17 Oṣù Ògún 2026 ní 13:14:03

Bi idile Adeleke ṣe gbajumọ nidi eto okoowo, oṣelu, agbo ariya, beẹ ni wọn ko gbẹyin lawọn ẹka bii eto amofin ati awọn miran.

“Orí ló kó wa yọ tí APC ò wọlé l’Osun, ọ̀pọ̀ wa kò bá fiṣẹ́ sílẹ̀ ni”- Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Osun

"Orí ló kó wa yọ tí APC ò wọlé l'Osun, ọ̀pọ̀ wa kò bá fiṣẹ́ sílẹ̀ ni"- Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Osun

Ọjọ́ Ajé, 17 Oṣù Ògún 2026 ní 16:12:22

Awọn oṣiṣẹ naa fi idunnu wọn han lori ija iṣẹgun ti gomina Adeleke ja to si bori rẹ

Kí ló dé tí Super Falcons ṣe lulẹ̀ ní WAFCON? Àjọ eléré bọ́ọ̀lù Nàíjíríà, NFF bẹ̀rẹ̀ ìwádìí, bó se júwe ọ̀nà ilé fún akọ́nimọ̀-ọ́n-gbá wọn

Kí ló dé tí Super Falcons ṣe lulẹ̀ ní WAFCON? Àjọ eléré bọ́ọ̀lù Nàíjíríà, NFF bẹ̀rẹ̀ ìwádìí, bó se júwe ọ̀nà ilé fún akọ́nimọ̀-ọ́n-gbá wọn

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 18 Oṣù Ògún 2026 ní 07:08:03

Awọn alakoso ajọ naa lo kede igbesẹ tuntun naa loju opo ‘X’ lọjọ Aje, ọsẹ yiii, ti wọn si jẹ ko di mimọ pe awọn ko le kawọ gbera lati jẹ ki ina Super Falcons maa jo ajorẹyin.

Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa

Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 18 Oṣù Ògún 2026 ní 11:18:02

BBC se iwadii nipa bi ẹyẹ Igun, anfaani rẹ, se n tan lọ nilẹ Afirika ati awọn ewu to rọ mọ ọ.

Ìjọ Mímọ́ CCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ẹ̀sùn táwọn èèyàn fi kan Olùṣọ́ ọ̀rẹ́kùnrin Tope Osoba lóri ohun tó ṣokùnfà ikú rẹ̀

Ìjọ Mímọ́ CCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ẹ̀sùn táwọn èèyàn fi kan Olùṣọ́ ọ̀rẹ́kùnrin Tope Osoba lóri ohun tó ṣokùnfà ikú rẹ̀

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Ògún 2026 ní 09:17:58

Ijọ CCC gbe iwadii yii dide latari awuyewuye to n lọ lori ayelujara wi pe o ṣee ṣe ki ọrẹkunrin rẹ, Ọgbẹni Itunu Onadeko, to jẹ Oluṣọ ijọ CCC to wa ni Bogije, ni Ibeju-Lekki niluu Eko mọ nipa iku rẹ.

Àwọn ọmọ gbajúmọ̀ akọrin Juju St. Janet ṣàlàyé ohun tó ṣekúpa gbajúgbajà Olórin náà

Àwọn ọmọ gbajúmọ̀ akọrin Juju St. Janet ṣàlàyé ohun tó ṣekúpa gbajúgbajà Olórin náà

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Ògún 2026 ní 17:05:54

Ninu ifọrọwerọ ti o ṣe pẹlu ileeṣẹ iroyin ori ayelujara kan, akọbi St. Janet, Fola St. Janet, ṣalaye wi pe ṣadeede ni akọrin naa bẹrẹ sii di mọ aya rẹ lọjọ ti o ku.

Wo àwọn agbègbè tí INEC sọ pé ó ṣeéṣe kí wàhálà bẹ́ sílẹ̀ lásìkò ìbò gómìnà Sátidé ní Osun

Wo àwọn agbègbè tí INEC sọ pé ó ṣeéṣe kí wàhálà bẹ́ sílẹ̀ lásìkò ìbò gómìnà Sátidé ní Osun

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Ògún 2026 ní 14:10:52

Ajọ INEC si ti ke si awọn ẹṣọ̀ alaabo lati san ṣokoto wọn ko le daindain lati pa ina igbesẹ yoowu lati la idibo ru.

Àjọ NiMet kéde ìpínlẹ̀ 19 tó ṣeéṣe kí omiyalé tún kọlù ní Naijiria

Àjọ NiMet kéde ìpínlẹ̀ 19 tó ṣeéṣe kí omiyalé tún kọlù ní Naijiria

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Ògún 2026 ní 13:10:37

Gẹgẹ bi ajọ naa ṣe kede louj po X rẹ, awọn ojo yoo ṣu lawọn ipinlẹ kan ni ariwa Naijiria laarọ oni Ọjọru, nigba ti ojo yoo rọ lawọn ipinlẹ kan bii Adamawa, Taraba, Bauchi, Gombe, Jigawa, Kaduna ati Kano.

Èló lowó oṣù táwọn ọmogun Naijiria tó wà lójú ìjà ń gbà? Àlàyé rèé

Èló lowó oṣù táwọn ọmogun Naijiria tó wà lójú ìjà ń gbà? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Ògún 2026 ní 15:41:40

Ṣaaju ni Aarẹ Bola Tinubu sọ pe ijọba gbọdọ ṣe atilẹyin fawọn ẹṣọ eleto aabo bi wọn ṣe n ṣiṣẹ ilu.

Kókó tó wà nínú lẹ́tà tí Davido fi ránṣẹ́ sí Donald Trump lórí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ l’Osun ṣáájú ìbò Gómìnà tó ń bọ̀

Kókó tó wà nínú lẹ́tà tí Davido fi ránṣẹ́ sí Donald Trump lórí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ l'Osun ṣáájú ìbò Gómìnà tó ń bọ̀

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Ògún 2026 ní 14:42:13

Davido ṣalaye ninu ọrọ to fi ranṣẹ si Trump loju opo X rẹ pe ‘‘ibẹru-bojo ti gbalẹ bayii, o si ṣee ṣe ki rogbodiyan bẹ silẹ lasiko ibo gomina ọjọ Satide to n bọ.’’

Ooni Ile Ife kéde orúkọ ọmọbìrin rẹ̀ tuntun

Ooni Ile Ife kéde orúkọ ọmọbìrin rẹ̀ tuntun

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Ògún 2026 ní 11:53:11

Ọjọ kẹjọ lẹyin ti Olori Oluwatosin Ogunwusi bi ọmọbinrin tuntun naa ni ayẹyẹ isọmọlorukọ ọhun waye.

Má forúkọ mi ṣe ìpolongo ìbò mọ́, Makinde dá a padà fún Oriyomi

Má forúkọ mi ṣe ìpolongo ìbò mọ́, Makinde dá a padà fún Oriyomi

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Ògún 2026 ní 07:18:00

Makinde wa rọ àwọn eeyan to n dupo òṣèlú wí pé ki wọn gbaju mọ nnkan ti wọn ba fẹ ṣe fawọn eeyan ipinlẹ Oyo, dipo bi wọn ṣe n bu oun kaakiri.

Olùdìbò 1.9m ni wọ́n ti n gbaradì fún ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun – INEC

Olùdìbò 1.9m ni wọ́n ti n gbaradì fún ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun – INEC

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 15 Oṣù Ògún 2026 ní 09:20:44

Gbogbo awọn oludije, alatilẹyin oludibo, alẹnulọrọ nidi oṣelu, to fi mọ awọn araalu ni wọn ti wa ni igbaradi eto idibo idibo gomina ọhun.

Wo bí àwọn obìnrin Afghanistan tíjọba Taliban fòfin dè pé wọn ò gbọdọ̀ gbá bọ́ọ̀lù ṣe di agbábọ́ọ̀lù nílẹ̀ òkèèrè

Wo bí àwọn obìnrin Afghanistan tíjọba Taliban fòfin dè pé wọn ò gbọdọ̀ gbá bọ́ọ̀lù ṣe di agbábọ́ọ̀lù nílẹ̀ òkèèrè

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Ògún 2026 ní 14:25:52

Lati ọdun 2021 ti awọn Taliban ti gbajọba ni wọn ti fofin de awọn obinrin wi pe wọn o gbọdọ kopa ninu ere bọọlu atawọn ere idaraya mii.

Kí ló fa ikú obìnrin tí wọn bá òkú rẹ̀ ní ọgbà Ṣọ́ọ̀ṣì l‘Osun, ta ló gé ìka ọwọ́ rẹ̀ lọ?

Kí ló fa ikú obìnrin tí wọn bá òkú rẹ̀ ní ọgbà Ṣọ́ọ̀ṣì l‘Osun, ta ló gé ìka ọwọ́ rẹ̀ lọ?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 18 Oṣù Ògún 2026 ní 08:21:58

Atẹjade kan ti alukoro ileesẹ ọlọpaa nilẹ wa, Ani Iniedu, fisita lo sisọ loju isẹlẹ yii pẹlu afikun pe awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ti lọ se ayẹwo si oku obinrin naa ni kete ti wọn gbọ nipa rẹ.