world-service-rss

BBC News Yorùbá

“Ìyá mi ti kú, òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì ni bàbá mi, mò ń fi ìwé ẹ̀rí NCE ta Puff-puff, kí gómìnà Adeleke tó gbà mí síṣẹ́”

"Ìyá mi ti kú, òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì ni bàbá mi, mò ń fi ìwé ẹ̀rí NCE ta Puff-puff, kí gómìnà Adeleke tó gbà mí síṣẹ́"

Ọjọ́rú, 10 Oṣù Owewe 2025 ní 10:20:20

BBC News Yorùbá kàn sí obìnrin tó ń ta Puffpuff, Oluwatosin Adejumo, ẹni tí gómìnà Ademola Adeleke fún ní ìṣẹ́ nígbà tó pàdé rẹ̀, ó sọ ọ̀pọ̀ ìpeníjà rẹ̀ kó tó rìn pàdé aláànú.

Israel yin àdó ikú mọ́ ikọ Hamas tó wà ní Doha, èèyàn mẹ́fà pàdánù ẹ̀mí

Israel yin àdó ikú mọ́ ikọ Hamas tó wà ní Doha, èèyàn mẹ́fà pàdánù ẹ̀mí

Ọjọ́rú, 10 Oṣù Owewe 2025 ní 09:19:56

Bo tilẹ jẹ pe ko si ẹgbẹ kankan to tii kede pe oun lo wa nidi ikọlu naa, ẹgbẹ Hamas ti kan sara si ikọlu ọhun.

Aráàlú tó ń ṣe ìwọ́de tako àjẹbánu ìjọba sọ iná sílé aṣòfin, èèyàn 21 kú

Aráàlú tó ń ṣe ìwọ́de tako àjẹbánu ìjọba sọ iná sílé aṣòfin, èèyàn 21 kú

Ọjọ́rú, 10 Oṣù Owewe 2025 ní 06:12:56

Lati ọjọ Aje ni awọn eeyan naa ti bẹrẹ iwọde ọhun, ki wọn to yabo ile igbimọ aṣofin naa.

Ìjọba àpapọ̀ kéde iṣẹ́ ìmọ̀ ẹ̀kọ́ tuntun fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ láti Pri 1 sí SS3

Ìjọba àpapọ̀ kéde iṣẹ́ ìmọ̀ ẹ̀kọ́ tuntun fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ láti Pri 1 sí SS3

Ọjọ́rú, 10 Oṣù Owewe 2025 ní 05:57:53

Ijọba ni eyii ṣe pataki fun awọn akẹkọọ lati maa kọ nipa nnkan ti yoo wulo fun ọjọ ọla wọn nikan.

NUPENG ṣẹ́wélé ìyanṣẹ́lódì lẹ́yìn àdéhùn pẹ̀lú iléeṣẹ́ ìpọnpo Dangote

NUPENG ṣẹ́wélé ìyanṣẹ́lódì lẹ́yìn àdéhùn pẹ̀lú iléeṣẹ́ ìpọnpo Dangote

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 21:22:27

Awọn awakọ ti ṣalaye ẹdun ọkan wọn lori itaporogan ti waye laarin awọn igun mejeeji yii, eyi ti wọn sọ pe o le tun wa ọwọngogo epo ati ẹkunwo ọkọ jakejado Naijiria.

Ìbẹ̀rù mú ọ̀pọ̀ èèyàn bí wọ́n ṣe rí epo dísù nínú kànga n’Ibadan èyí tí ọ̀pọ̀ èèyàn ń gbọ́n

Ìbẹ̀rù mú ọ̀pọ̀ èèyàn bí wọ́n ṣe rí epo dísù nínú kànga n'Ibadan èyí tí ọ̀pọ̀ èèyàn ń gbọ́n

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 10:48:05

Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọ pe iwadii awọn fi han pe o ṣee ṣe ko jẹ pe lati inu tanki kan ti wọn ri mọlẹ ni epo disu naa ti n jo lọ sinu kangan ọhun.

Àwọn ológun Israel pàṣẹ fún gbogbo olùgbé Gaza láti kúrò torí ìkọlù ńlá ń bọ̀

Àwọn ológun Israel pàṣẹ fún gbogbo olùgbé Gaza láti kúrò torí ìkọlù ńlá ń bọ̀

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 11:24:54

Itumọ eyi ni pe Israel n paṣẹ pe ki eeyan ti iye wọn to miliọnu kan, kuro ni agbegbe to tobi ju ni Gaza.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 12:51:49

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

“Ọdẹ ìbílẹ̀ ni bàbá, ìyá àti ọkọ mi, Fijilańté tó ṣọ́ Aláàfin Adeyemi àti Owoade ni mí”

"Ọdẹ ìbílẹ̀ ni bàbá, ìyá àti ọkọ mi, Fijilańté tó ṣọ́ Aláàfin Adeyemi àti Owoade ni mí"

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 10:04:13

BBC News Yorùbá tàkurọ̀sọ pẹ̀lú ọdẹ ìbílẹ̀ obìnrin tó wà ní ààfin Oyo, ẹni tó ṣàl]ayé bó ṣe dé ìdí iṣẹ́ ọdẹ, ọ̀pọ̀ ìpèníjà tó kojú àti àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn Aláàfin.

Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìpàdé NUPENG, Dangote àti ìjọba ṣe forí ṣánpọ́n, tí ìyanṣẹ́lódì àwọn awakọ̀ epo sì wọ ọjọ́ kejì

Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìpàdé NUPENG, Dangote àti ìjọba ṣe forí ṣánpọ́n, tí ìyanṣẹ́lódì àwọn awakọ̀ epo sì wọ ọjọ́ kejì

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 08:47:05

Awọn ibudo ti NUPENG n ja epo si tẹlẹ kaakiri orilẹede yii ni wọn ti pa lọjọ Aje, lati fi ẹhonu han si ileesẹ elepo Dangote.

Ebenezer Obey fọnmú, figbe ta, bí ariwo ikú rẹ̀ ṣe tún gbalẹ̀ tan tan tan

Ebenezer Obey fọnmú, figbe ta, bí ariwo ikú rẹ̀ ṣe tún gbalẹ̀ tan tan tan

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 07:34:56

Ninu fọnran kan to gbe sori ayelujara, Ebenezer Obey ni iroyin ẹlẹjẹ ti ko fẹsẹ mulẹ rara ni iroyin iku rẹ naa.

Agbébọn kọlu ibùdókọ̀ ní Jerusalem, ṣekúpa èèyàn mẹ́fà, mẹ́jọ farapa, lásìkò tí wọ́n ń lọ ibiṣẹ́

Agbébọn kọlu ibùdókọ̀ ní Jerusalem, ṣekúpa èèyàn mẹ́fà, mẹ́jọ farapa, lásìkò tí wọ́n ń lọ ibiṣẹ́

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 05:40:54

Bo tilẹ jẹ pe ko si ẹgbẹ kankan to tii kede pe oun lo wa nidi ikọlu naa, ẹgbẹ Hamas ti kan sara si ikọlu ọhun.

Kí ni ìtúmọ̀ Falana gbọ́ tìẹ, ọ̀nà wo ló fi le ṣe ìrànwọ́ fún ìlera ọpọlọ rẹ?

Kí ni ìtúmọ̀ Falana gbọ́ tìẹ, ọ̀nà wo ló fi le ṣe ìrànwọ́ fún ìlera ọpọlọ rẹ?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 06:00:06

Dokita Nawaf Al-Rifai to jẹ onimọ nipa ọrọ inu ọkan eniyan nile iwosan Irbid Medical Consulting Centre ni Jordan ṣalaye pe awọn eeyan maa n rinrin ajo ninu ọkan wọn lọ sibi awọn nnkan to ti ṣẹlẹ ṣẹyin ati nnkan to le ṣẹlẹ lọjọ iwaju.

Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, Atiku, Obi àti ẹgbẹ́ èèyàn àríwá fajúro, bí Boko Haram ṣe pa èèyàn tó lé ní ọgọ́ta, wọn dábàá ọ̀nà àbáyọ sí ìkọlù agbébọn

Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, Atiku, Obi àti ẹgbẹ́ èèyàn àríwá fajúro, bí Boko Haram ṣe pa èèyàn tó lé ní ọgọ́ta, wọn dábàá ọ̀nà àbáyọ sí ìkọlù agbébọn

Ọjọ́ Ajé, 8 Oṣù Owewe 2025 ní 12:09:29

Ilu Darul Jamal, to jẹ ibi ti ikọ ọmọ ogun Naijiria n tẹdo si ni ala Naijiria ati Cameroon ni ikọlu naa ti waye, nibi ti wọn ti ṣekupa ọmọ ogun marun un.

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Òṣùpá Ẹlẹ́jẹ̀ tó yọ lójú ọ̀run ní Naijiria lálẹ́ àná àtàwọn orílẹ́èdè míì

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Òṣùpá Ẹlẹ́jẹ̀ tó yọ lójú ọ̀run ní Naijiria lálẹ́ àná àtàwọn orílẹ́èdè míì

Ọjọ́ Ajé, 8 Oṣù Owewe 2025 ní 11:15:37

Gẹgẹ bi alaye tawọn onimọ nipa oju ọrun sọ, eyi maa n ṣẹlẹ nigba ti aye ba wa laarin oorun ati oṣupa, ti o si n di imọlẹ lati ara oorun si oṣupa.

“Òpó iná IKEDC ló wó lù mí lọ́dún méje sẹ́yìn, ń kò le rìn tàbí dá jẹun, ọ̀rá ni mo fi ń tọ̀, owó ti tán, mo ná N3m láti wo egbò ara mi”

"Òpó iná IKEDC ló wó lù mí lọ́dún méje sẹ́yìn, ń kò le rìn tàbí dá jẹun, ọ̀rá ni mo fi ń tọ̀, owó ti tán, mo ná N3m láti wo egbò ara mi"

Ọjọ́ Ajé, 8 Oṣù Owewe 2025 ní 10:43:13

BBC News Yorùbá bá obìnrin kan tó di aláàbọ̀ ara lójijì sọ̀rọ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ tó pa kádàrá rẹ̀ dà, ìnira tó ń là kọjá àti ìrànwọ́ tó fẹ́ lọ́dọ̀ iléeṣẹ́ tó ní ó fa sábàbí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.

Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìpàdé NUPENG, Dangote àti ìjọba ṣe forí ṣánpọ́n, tí ìyanṣẹ́lódì àwọn awakọ̀ epo sì wọ ọjọ́ kejì

Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìpàdé NUPENG, Dangote àti ìjọba ṣe forí ṣánpọ́n, tí ìyanṣẹ́lódì àwọn awakọ̀ epo sì wọ ọjọ́ kejì

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 9 Oṣù Owewe 2025 ní 08:47:05

Awọn ibudo ti NUPENG n ja epo si tẹlẹ kaakiri orilẹede yii ni wọn ti pa lọjọ Aje, lati fi ẹhonu han si ileesẹ elepo Dangote.

Ìjọba Amẹrika ṣe àtúnṣe òfin Físà gbígbà, wo bó ṣe kàn ọ́

Ìjọba Amẹrika ṣe àtúnṣe òfin Físà gbígbà, wo bó ṣe kàn ọ́

Ọjọ́ Ajé, 8 Oṣù Owewe 2025 ní 05:40:48

Iroyin ni atunṣẹ tuntun yii ko ṣẹyin bi awọn eeyan kan ṣe maa n rinrinajo lọ si orilẹede mii yatọ si orilẹede wọn lati kọwe beere fun fisa Amẹrika.

Wo Ọba kan nílẹ̀ Yorùbá tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ ọdún kan láti fi ṣe ètùtù

Wo Ọba kan nílẹ̀ Yorùbá tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ ọdún kan láti fi ṣe ètùtù

Ọjọ́ Ajé, 8 Oṣù Owewe 2025 ní 05:43:09

Ọjọ́ kẹwàá oṣù kìíní ọdún 1949 ni ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn tí Ọba ṣe ní ìlú Ẹ̀fọ̀n-Aláayè ní ìpínlẹ̀ Ekiti wáyé.

Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, Atiku, Obi àti ẹgbẹ́ èèyàn àríwá fajúro, bí Boko Haram ṣe pa èèyàn tó lé ní ọgọ́ta, wọn dábàá ọ̀nà àbáyọ sí ìkọlù agbébọn

Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, Atiku, Obi àti ẹgbẹ́ èèyàn àríwá fajúro, bí Boko Haram ṣe pa èèyàn tó lé ní ọgọ́ta, wọn dábàá ọ̀nà àbáyọ sí ìkọlù agbébọn

Ọjọ́ Ajé, 8 Oṣù Owewe 2025 ní 12:09:29

Ilu Darul Jamal, to jẹ ibi ti ikọ ọmọ ogun Naijiria n tẹdo si ni ala Naijiria ati Cameroon ni ikọlu naa ti waye, nibi ti wọn ti ṣekupa ọmọ ogun marun un.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọ̀pọ̀ ‘Olosho’ àti àwọn ọmọbinrin tó ń ṣe ‘hookup’ ni ayélujára ti sọ di oníṣẹ́ gidi lọ́wọ́ - Peller

Ọ̀pọ̀ 'Olosho' àti àwọn ọmọbinrin tó ń ṣe 'hookup' ni ayélujára ti sọ di oníṣẹ́ gidi lọ́wọ́ - Peller

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 6 Oṣù Owewe 2025 ní 08:03:15

Peller pe nigba ti oun bẹrẹ, bii ki eeyan marun, mẹta maa wo oun lori ayelujara ni, oun a dẹ tun maa pariwo tatata ni.

“Wọ́n fipá gbẹ̀jẹ̀ lára mi, mi ò rówó oṣù gbà, wọ́n lù mí lálù dákú ní Libya kí orí tó kó mi yọ”

"Wọ́n fipá gbẹ̀jẹ̀ lára mi, mi ò rówó oṣù gbà, wọ́n lù mí lálù dákú ní Libya kí orí tó kó mi yọ"

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 6 Oṣù Owewe 2025 ní 08:13:31

Mercy Oluwagbenga ni oun ṣakiyesi pe nọọsi to n tọju mama wọn to n ṣaisan naa lo n gba ẹjẹ oun ni gbogbo igba lai mu oun lọ sile iwosan.

“Ọmọ ọdún méjìlélógún ni mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe ìyá fún àwọn ọmọ méjìléláàdọ́ta tí kò ní ìyá”

"Ọmọ ọdún méjìlélógún ni mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe ìyá fún àwọn ọmọ méjìléláàdọ́ta tí kò ní ìyá"

Ọjọ́ Ẹtì, 5 Oṣù Owewe 2025 ní 08:35:42

Joy ṣalaye pe oun le ni ẹni ọgbọn ọdun ki oun to pade ọkọ oun, nitori gbogbo awọn ti o n kọ ẹnu ifẹ si oun saaju ni wọn maa n sa lọ ti oun ba ti mu wọn de ile ti oun ti n tọju awọn ọmọ alainiya naa.

Ìyá tí wọ́n pa ọmọ rẹ̀ torí obìnrin l’Ekiti ń bèèrè ìdájọ́ òdodo

Ìyá tí wọ́n pa ọmọ rẹ̀ torí obìnrin l'Ekiti ń bèèrè ìdájọ́ òdodo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 6 Oṣù Owewe 2025 ní 10:00:20

Obinna Collins, ọkan lara awọn aburo oloogbe to ba wa sọrọ lori iku naa, ṣàlàyé pe ọrẹ ni Chukwuemeka jẹ si awọn to ṣeku pa a.

Nǹkan àràmàǹdà méje tó ṣẹlẹ̀ lásìkò tí wọ́n bí Anabi Muhammad

Nǹkan àràmàǹdà méje tó ṣẹlẹ̀ lásìkò tí wọ́n bí Anabi Muhammad

Ọjọ́ Ẹtì, 5 Oṣù Owewe 2025 ní 13:57:54

Idile Abdullah bin Al-Muttalib ati Amina bint Wahb iyawo rẹ ni a bi Anabi Muhammad si lọdun 570

Àrùn Ebola tún ṣẹ́yọ, pa èèyàn 15 ní DR Congo

Àrùn Ebola tún ṣẹ́yọ, pa èèyàn 15  ní DR Congo

Ọjọ́ Ẹtì, 5 Oṣù Owewe 2025 ní 12:06:46

Obinrin alaboyun ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn kan ni wọn kọkọ fidi rẹ mulẹ pe Ebola tuntun naa kọlu loṣu Kẹjọ, ti wọn si da a duro sile iwosan fun itọju.

Ààrẹ Tinubu tún ti tẹkọ̀létí ròkè òkun, ipò wo ni Tinubu wà láàrín àwọn Ààrẹ tó rìnrìnàjò jùlọ?

Ààrẹ Tinubu tún ti tẹkọ̀létí ròkè òkun, ipò wo ni Tinubu wà láàrín àwọn Ààrẹ tó rìnrìnàjò jùlọ?

Ọjọ́ Ẹtì, 5 Oṣù Owewe 2025 ní 10:25:00

Isinmi ọlọjọ mẹwaa yii waye lẹyin ti aarẹ ti kọkọ gba ọkan ni oṣu kẹwaa ọdun 2024.

‘Àìsàn ibà lásán ló ṣe Shina, ọmọ Peju Ogunmola kó tó ò kú’

'Àìsàn ibà lásán ló ṣe Shina, ọmọ Peju Ogunmola kó tó ò kú'

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Owewe 2025 ní 08:41:46

ilu Eko ni wọn ni Shina wa laarin awọn ọrẹ rẹ ti wọn jọ n ṣe iṣẹ orin ko to di pe o ni aisan iba ro si wa sile ki iya rẹ le tọju rẹ.

Àsìkò tí ọmọ mi fẹ́ẹ́ ṣí ilé ìtajà ìgbàlódé fún mi ló jáde láyé- Ìya Sanku

Àsìkò tí ọmọ mi fẹ́ẹ́ ṣí ilé ìtajà ìgbàlódé fún mi ló jáde láyé- Ìya Sanku

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Owewe 2025 ní 17:32:18

Ninu alaye rẹ, Iya Sanku ṣalaye pe ata ni oun ta, ọpọ ọdun si ni Oloogbe Samad fi ba ohun ta tomato ati awọn eroja ọbe, ko too lu aluyo ninu iṣẹ aderin-in-poṣonu to yan laayo.

Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún ọkọ tó dáná sun ìyàwó rẹ̀ láàyè nítorí àwọ̀ ara obìnrin náà

Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún ọkọ tó dáná sun ìyàwó rẹ̀ láàyè nítorí àwọ̀ ara obìnrin náà

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Owewe 2025 ní 05:53:31

Ninu ọrọ to sọ ṣaaju iku rẹ, Lakshmi ṣalaye pe ọkọ oun torukọ rẹ n jẹ Kishandas, maa n daamu oun nitori awọ dudu ti oun ni.

Wo bí ètò ìgbadé Rashidi Ladoja gẹ́gẹ́bí Olubadan tuntun yóò ṣe lọ

Wo bí ètò ìgbadé Rashidi Ladoja gẹ́gẹ́bí Olubadan tuntun yóò ṣe lọ

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Owewe 2025 ní 10:43:11

Kọmiṣanna eto iroyin nipinlẹ Oyo, Ọmọọba Dotun Oyelade, ṣalaye pe eto igbade naa yoo bẹrẹ lọjọ Aje, ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹsan-an ọdun 2025.

Èèyàn 32 jáde láyé nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi ní ìpínlẹ̀ Niger

Èèyàn 32 jáde láyé nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi ní ìpínlẹ̀ Niger

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Owewe 2025 ní 12:35:23

Ọkọ̀ ojú omi náà, tó jẹ́ onípákó, ni ìròyìn sọ pé ó kó àwọn èrò 138, tó sì dànù ní ọ̀gangan Shagunu-Dunga ní odò Kainji.

Kí ni ‘Maulud Nabiy’ àti ìdí tí èrò àwọn Mùsùlùmí fi yàtọ̀ lóríi rẹ̀?

Kí ni 'Maulud Nabiy' àti ìdí tí èrò àwọn Mùsùlùmí fi yàtọ̀ lóríi rẹ̀?

Ọjọ́ Ẹtì, 5 Oṣù Owewe 2025 ní 07:04:30

Ki i ṣe gbogbo Musulumi aye lo n sami ayẹyẹ ọjọọbi naa, bi awọn kan ṣe sọ ọ di ko ṣee ma ṣe, ti wọn yoo gun ẹṣin yipo ilu tilu-tifọn, bẹẹ ni awọn Musulumi kan sọ pe ẹṣẹ nla ni ki eeyan ṣe Mọludi ninu Islam.

Aráàlú ní kí ìjọba rọjo àdó olóró síbùba àwọn ajínigbé lẹ́yìn ikú baba àti ọmọ ní Kwara

Aráàlú ní kí ìjọba rọjo àdó olóró síbùba àwọn ajínigbé lẹ́yìn ikú baba àti ọmọ ní Kwara

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Owewe 2025 ní 16:32:53

Iṣẹlẹ yii waye lẹyin ti iroyin gbee pe awọn agbebọn kan ti wọn to meje niye yabo Mọsalasi kan ni ilu Lade ni ijọba ibilẹ Patigi, ti wọn si pa baba ati ọmọ rẹ nigba ti wọn kirun tan.

Peju Ogunmola, àgbà òṣèré, tó tilé òṣèré jáde, tó tún di aya àgbà òṣèré

Peju Ogunmola, àgbà òṣèré, tó tilé òṣèré jáde, tó tún di aya àgbà òṣèré

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Owewe 2025 ní 13:47:29

Peju Ogunmola wa lati idile awon oṣere. O jẹ ọmọ fun agba oṣere to tun jẹ onkọtan, Kola Ogunmola

Ọdún egúngún di yánpọnyánrin nílùú Eko, èèyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn

Ọdún egúngún di yánpọnyánrin nílùú Eko, èèyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Owewe 2025 ní 10:13:11

Olugbe agbegbe to ba ileeṣẹ iroyin abẹle, The Punch ni iṣẹlẹ ja si rogbodiyan lẹyin ti ọdun eegun naa pari.

Ìyàwó Mohbad ní òun ṣetán láti ṣàyẹ̀wò DNA fún Liam, bàbá Mohbad ní ìlú òyìnbó lòun ti fẹ́ kí wọ́n ṣe é

Ìyàwó Mohbad ní òun ṣetán láti ṣàyẹ̀wò DNA fún Liam, bàbá Mohbad ní ìlú òyìnbó lòun ti fẹ́ kí wọ́n ṣe é

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Owewe 2025 ní 14:27:34

Agbẹjọro Wunmi, Ọgbẹni Kabir Akingbolu sọ pe Wunmi o figba kankan sa fun ayẹwo DNA fun Liam, o ni baba Mohbad naa ni ko fi ara rẹ silẹ lati ṣe ayẹwo naa fun ọmọ Mohbad.

Ààrẹ yọ adájọ́ àgbà nípò lórí ẹ̀sùn àṣìlò ipò tí àráàlú kan fi kàn án

Ààrẹ yọ adájọ́ àgbà nípò lórí ẹ̀sùn àṣìlò ipò tí àráàlú kan fi kàn án

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Owewe 2025 ní 09:45:36

Igbesẹ yii ko ṣẹyin imọran igbimọ kan to ṣewadi ẹsun ti ọmọbibi Ghana kan, Daniel Ofori, fi kan adájọ́ agba naa.

Iléeṣẹ́ aṣojú America sọ ìdí tó fi ń fagilé físà àwọn ọmọ Naijiria

Iléeṣẹ́ aṣojú America sọ ìdí tó fi ń fagilé físà àwọn ọmọ Naijiria

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Owewe 2025 ní 17:25:32

Loṣu to kọja yii ni US kede pe oun yoo ṣe agbeyẹwo fisa awọn ọmọ Naijiria ati awọn ilu mi-in lagbaaye, kawọn le tete gbe igbesẹ to yẹ bi wọn ba rufin.

‘Àwọn tó jí mi gbé yìnbọn mọ́ mi, wọ́n fi mí sílẹ̀ l’ágbàrá ẹ̀jẹ̀ láì mọ̀ pé mi ò tíì kú’

'Àwọn tó jí mi gbé yìnbọn mọ́ mi, wọ́n fi mí sílẹ̀ l'ágbàrá ẹ̀jẹ̀ láì mọ̀ pé mi ò tíì kú'

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Owewe 2025 ní 19:25:44

Lẹyin ọjọ kẹrin ti wọn ji i gbe, ifiyajẹni naa n tẹsiwaju nigba ti wọn gbe Sativa lọ si ibi ti a mọ si Katavi National Park. Ibudo yii kun fun oniruuru ẹranko buruku, bẹẹ ni wọn wọ ọ lọ siwaju odo kan bii ki wọn ju u sibẹ ko ku. Oun naa sọ ọ, pe o daju pe awọn to ji oun gbe naa ko fẹ ki oun yè, wọn fẹẹ gba ẹmi lẹnu oun patapata ni.

Ó tún ti ń rúgbó bọ̀ l’Ogbomosho, Ṣoun Ghandi Laoye ń forígbárí pẹ̀lú ẹgbẹ́ ọmọbíbí ìlú Ogbomosho kan

Ó tún ti ń rúgbó bọ̀ l'Ogbomosho, Ṣoun Ghandi Laoye ń forígbárí pẹ̀lú ẹgbẹ́ ọmọbíbí ìlú Ogbomosho kan

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Owewe 2025 ní 12:01:54

Awọn oloye ẹgbẹ naa ko ṣai fidi rẹ mulẹ wi pe awọn ko tabuku tabi ṣe arifin si kabiyesi, ṣugbọn awọn n tẹle nnkan to wa ninu ofin ẹgbẹ naa ni.

Ta ni Sanku Comedy, gbajúmọ̀ aláwàdà orí ayélujára, tí ikú rẹ̀ ń milẹ̀ tìtì?

Ta ni Sanku Comedy, gbajúmọ̀ aláwàdà orí ayélujára, tí ikú rẹ̀ ń milẹ̀ tìtì?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Owewe 2025 ní 14:18:01

Iroyin ijamba ọkọ ọhun ti a gbọ pe o ṣẹlẹ niluu Odo-Oba lopopona Oyo si Ogbomoso lo ti mi ori ayelaujara titi lati ana ọjọ Aje titi ti oni.

Ta ni Ruth Otabor, àbúrò Phyna tí ọkọ̀ iléeṣẹ́ Dangote ṣokùnfà ikú rẹ̀?

Ta ni Ruth Otabor, àbúrò Phyna tí ọkọ̀ iléeṣẹ́ Dangote ṣokùnfà ikú rẹ̀?

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Owewe 2025 ní 10:12:29

Ní ọjọ́ Kọkànlélọ́gbọ̀n, oṣù Kẹjọ, ọdún 2025 ni ẹbí Ruth fi àtẹ̀jáde kan látọwọ́ iléeṣẹ́ agbẹjọ́rò kan tí orúkọ ń jẹ́ Eko Solicitors & Advocates kéde ikú Ruth, tí wọ́n sì nǹkan bíi aago mẹ́fà ààbọ̀ òwúrọ̀ ló jáde láyé.

Kí ni òfin Islam sọ nípa ìpànìyàn nítorí sísọ ọ̀rọ̀ òdì sí Anabi?

Kí ni òfin Islam sọ nípa ìpànìyàn nítorí sísọ ọ̀rọ̀ òdì sí Anabi?

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Owewe 2025 ní 17:44:54

Àtẹ̀jáde tí agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Niger, Wasiu Abiodun fi léde lọ́jọ́ Àìkú, ọjọ́ Kọkànlélọ́gbọ̀n, oṣù Kẹjọ, ọdún 2025 sọ pé àwọn èèyàn náà ti dáná sun obìnrin náà tán kó tó di pé àwọn ọlọ́pàá ríbi débẹ̀.