world-service-rss

BBC News Yorùbá

Ọ̀nà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni Ọlọ́run ń gbà bá èèyàn sọ̀rọ̀, kò yẹ kí ẹ̀sìn máa fa ìjà - Bíṣọ́ọ̀bù Ladigbolu

Ọ̀nà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni Ọlọ́run ń gbà bá èèyàn sọ̀rọ̀, kò yẹ kí ẹ̀sìn máa fa ìjà - Bíṣọ́ọ̀bù Ladigbolu

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 14:25:37

Bíṣọ́ọ̀bù Ladigbolu tó jẹ́ àgbà ẹlẹ́sìn Kristẹni tó fẹ̀yìntì gẹ́gẹ́ bí Bíṣọ́ọ̀bù nínú ìjọ Methodist Church nínú ìfọ̀rọ̀wérò tó ṣe pẹ̀lú BBC News Yorùbá sọ pé òun kò rò pé ó yẹ kí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn máa dá ìjà sílẹ̀ rárá.

Àwọn akẹkọọ fásitì Ilesa fọnmú mọ́ ìjọba Osun lọ́wọ́ torí àfikún owó ilé ẹ̀kọ́ àti owó ilé tó ju agbára wọn lọ

Àwọn akẹkọọ fásitì Ilesa fọnmú mọ́ ìjọba Osun lọ́wọ́ torí àfikún owó ilé ẹ̀kọ́ àti owó ilé tó ju agbára wọn lọ

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 13:31:19

BBC News Yorùbá bá àwọn akẹkọ̀ọ́, ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ fásitì náà, ẹgbẹ́ alátakò àti ìjọba sọ̀rọ̀ lórí ìwọ́de náà.

Obasanjọ àti Danjuma ti pè mí rí lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ l’Abuja, wọn kò fi ológun halẹ̀ mọ́ mi – Wike

Obasanjọ àti Danjuma ti pè mí rí lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ l'Abuja, wọn kò fi ológun halẹ̀ mọ́ mi – Wike

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 09:31:14

Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wike ṣàlàyé faw Akọroyin lórí ìdí tó ṣe lọ sórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye pẹ̀lú ológun.

Àwọn asòfin Ondo bínú jáde níbi ìjókòó ilé torí abá àfikún ètò ìsúná ₦531bn tí Gomina Aiyedatiwa gbé lọ iwájú wọn

Àwọn asòfin Ondo bínú jáde níbi ìjókòó ilé torí abá àfikún ètò ìsúná ₦531bn tí Gomina Aiyedatiwa gbé lọ iwájú wọn

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 07:58:58

Ọkan lara awọn ọmọ ile aṣòfin Ondo to ba BBC News Yorùbá sọrọ, Ifabiyi Olatunji salaye pé àwọn n beere pe ki ni ijọba fi owo ti wọn buwọ lu saaju ṣe?

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 13:27:31

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Obasanjọ àti Danjuma ti pè mí rí lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ l’Abuja, wọn kò fi ológun halẹ̀ mọ́ mi – Wike

Obasanjọ àti Danjuma ti pè mí rí lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ l'Abuja, wọn kò fi ológun halẹ̀ mọ́ mi – Wike

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 09:31:14

Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wike ṣàlàyé faw Akọroyin lórí ìdí tó ṣe lọ sórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye pẹ̀lú ológun.

Ẹbí Aloba kìlọ̀ fún ìyàwó Mohbad láti máṣe jẹ́ orúkọ àwọn mọ́, Wunmi bá fárígá

Ẹbí Aloba kìlọ̀ fún ìyàwó Mohbad láti máṣe jẹ́ orúkọ àwọn mọ́, Wunmi bá fárígá

Ọjọ́ Ẹtì, 14 Oṣù Bélú 2025 ní 05:26:16

Àtẹ̀jáde kan tí olórí ẹbí náà, Omolayo Aloba àti Bàbá Mohbad, Joseoh Aloba fi léde lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun lo ṣàlàyé ọ̀rọ̀ yìí.

Ohun tó fa ikú èèyàn mẹ́fà àti ọ̀pọ̀ tó farapa lásìkò tí wọ́n fẹ́ gba iṣẹ́ ológun ní Ghana rèé

Ohun tó fa ikú èèyàn mẹ́fà àti ọ̀pọ̀ tó farapa lásìkò tí wọ́n fẹ́ gba iṣẹ́ ológun ní Ghana rèé

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 14:23:30

Awọn fidio lori ayelujara lanaa ode yii, ṣafihan bi awọn eeyan to fẹ gba iṣẹ ologun naa ṣe to lọ loju opopona.

Òṣèlú da oju ọ̀rọ̀ rú níbi ayẹyẹ ṣíṣí ilé ìkó-nǹkan ìṣẹ̀mbáyé sí oni $25m l’Edo, ariwo sọ

Òṣèlú da oju ọ̀rọ̀ rú níbi ayẹyẹ ṣíṣí ilé ìkó-nǹkan ìṣẹ̀mbáyé sí oni $25m l'Edo, ariwo sọ

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 12:59:23

Oniṣowo nla, Phillip Ihenacho, to jẹ adari eto ile iṣẹmabaye yii lo gbe MOWAA kalẹ.

Wo ohun mẹ́ta tí oríṣi gèlè wíwé ń sọ àti ohun tí ọ̀nà márùn-ún tí a ń gbà dé fìlà ń wí

Wo ohun mẹ́ta tí oríṣi gèlè wíwé ń sọ àti ohun tí ọ̀nà márùn-ún tí a ń gbà dé fìlà ń wí

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 12:30:57

BBC News Yorùbá wà ṣe àkójọpọ̀ àwọn ọ̀nà tí obìnrin ń gba wé gèlè àti ọ̀nà márùn-ún tí ọkùnrin ń gbà gẹ fìlà pẹ̀lú ohun tí àwọn ìlànà náà túmọ̀ sí.

Àlàyé rèé lórí bí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ tó fa aáwọ láàárín Wike àti ọmọ ológun ṣe jẹ́

Àlàyé rèé lórí bí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ tó fa aáwọ láàárín Wike àti ọmọ ológun ṣe jẹ́

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 10:23:58

Agbẹnusọ fún Nyesom Wike, Lere Olayinka ti wá ṣàlàyé bí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ tó fa aáwọ náà ṣe jẹ́.

Àgbà ọ̀jẹ̀ òṣèré tíátà, Oyewole Olowomojuore, tí a mọ̀ sí Bàbá Gébú, dágbére fáyé

Àgbà ọ̀jẹ̀ òṣèré tíátà, Oyewole Olowomojuore, tí a mọ̀ sí Bàbá Gébú, dágbére fáyé

Ọjọ́bọ, 13 Oṣù Bélú 2025 ní 04:41:39

Gbajugbaja òṣèré tíátà nni, Kunle Afod lo kede ikú Baba Gebu ni ojú òpó ayélujára Instagram rẹ̀.

'’Wike jẹ̀bí pé ó pe ọmogun ní òmúgọ̀ àmọ́ iléeṣẹ́ ológun gbọdọ̀ dá ṣèríà fún ọmogun tó gbéná wojú Wike, káwọn ọmogun má ba à dáwọ́jọ lu mínísítà lọ́jọ́ kan’’

''Wike jẹ̀bí pé ó pe ọmogun ní òmúgọ̀ àmọ́ iléeṣẹ́ ológun gbọdọ̀ dá ṣèríà fún ọmogun tó gbéná wojú Wike, káwọn ọmogun má ba à dáwọ́jọ lu mínísítà lọ́jọ́ kan''

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 12:30:54

Onimọ nipa eto aabo, Akin Adeyi ni iwa arifin ni ọmogun oju omi tawọn eeyan n gboriyin fun yii lori ayelujara hu si Wike, to jẹ minisita orilẹede Naijiria.

Wọ́n pè mí ní olè, ajagungbalẹ̀ lórí ọ̀nà Circular Road àmọ́ mi ò jẹ ẹnìkankan ní àlàyé - Makinde

Wọ́n pè mí ní olè, ajagungbalẹ̀ lórí ọ̀nà Circular Road àmọ́ mi ò jẹ ẹnìkankan ní àlàyé - Makinde

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 12:57:42

‎Olugbani-nimọran pataki fun Gomina Makinde lori idasilẹ ilu tuntun ati igboro, Mofoluke Adebiyi, sọrọ nipa isẹlẹ naa nibi ipade awọn oluwoye awujọ to waye niluu Ibadan.

Wo ipa tí bí ikọ̀ Super Eagles ṣe kọ̀ láti gbáradì fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn ọ́la, yóò ní lórí àṣèyọrí wọn

Wo ipa tí bí ikọ̀ Super Eagles ṣe kọ̀ láti gbáradì fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn ọ́la, yóò ní lórí àṣèyọrí wọn

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 11:15:57

Ifẹsẹwọnṣe naa ṣe pataki fun Super Eagles nitori ohun ni yoo sọ boya wọn ṣi le kopa ninu idije ife ẹye agbaye 2026 World Cup.

Ilé ẹ̀jọ́ gíga kò lágbára láti dá ẹjọ́ mi lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀, yóò dáa kò jáwọ̀ nínú rẹ̀ - Nnamdi Kanu

Ilé ẹ̀jọ́ gíga kò lágbára láti dá ẹjọ́ mi lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀, yóò dáa kò jáwọ̀ nínú rẹ̀ - Nnamdi Kanu

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 12:36:08

Kanu lo sọ bẹẹ ninu iwe kan to fi ṣọwọ si adajọ James Omotosho ninu eyii to ti sọ pe ko si ofin to kin ẹjọ ti ijọba n ba oun ṣe lẹyin.

Ilé ẹjọ́ ju bàbá tí wọn fẹ̀sùn kàn, pé ó lẹ̀dí àpò pọ̀ mọ́ ẹni tó fipá bá ọmọ rẹ̀, ọmọ ọdún márùn-ún lòpọ̀, sí àhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n

Ilé ẹjọ́ ju bàbá tí wọn fẹ̀sùn kàn, pé ó lẹ̀dí àpò pọ̀ mọ́ ẹni tó fipá bá ọmọ rẹ̀, ọmọ ọdún márùn-ún lòpọ̀, sí àhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 09:02:00

Adájọ́ Rita Oguguo fi bàbá náà sí àhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tí agbẹjọ́rò rẹ̀ yọjú sílé ẹjọ́ pé òun kò ṣe ẹjọ́ lórí lórí ọmọ òun tí wọ́n fi ipá bá lòpọ̀.

Àlàyé lórí bí ọ̀kan nínú Naijiria, Cameroon, DR Congo àti Gabon láti Afirika yóò ṣe yege fún play-off ẹlẹ́kùn-jẹkùn àgbáyé ti 2026 World Cup

Àlàyé lórí bí ọ̀kan nínú Naijiria, Cameroon, DR Congo àti Gabon láti Afirika yóò ṣe yege fún play-off ẹlẹ́kùn-jẹkùn àgbáyé ti 2026 World Cup

Ọjọ́rú, 12 Oṣù Bélú 2025 ní 05:43:36

Lẹyin ti wọn kuna lati pedege fun idije 2026 World Cup lati ilẹ Afririka, Cameroon, DR Congo, Gabon ati Naijiria yoo koju Mococco ni ọla lati mọ ikọ agbabọọlu kan ti yoo ṣoju Afirika ninu ifẹsẹwọnsẹ lati pegede fun idije ife ẹyẹ agbaye lọdun to n bọ.

Ṣé lóòtọ́ọ́ ni ẹ̀dínwó bá owó èròjà oúnjẹ́, kí ló fà á?

Ṣé lóòtọ́ọ́ ni ẹ̀dínwó bá owó èròjà oúnjẹ́, kí ló fà á?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Bélú 2025 ní 12:29:36

BBC News Yorùbá lọ sáwọn ọjà yíkà ilẹ̀ Yorùbá láti mọ̀ bóyá lóòtọ́ọ́ ní ẹ̀dínwó ti bá àwọn owó èròjà oúnjẹ́, àti pé kí ló fà á, àbọ̀ ìwádìí wa rèé.

Kí ni kókó ohun tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram àti ISWAP ń jà fún tí igba èèyàn ṣe tẹ́rí gbaṣọ́?

Kí ni kókó ohun tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram àti ISWAP ń jà fún tí igba èèyàn ṣe tẹ́rí gbaṣọ́?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Bélú 2025 ní 09:39:07

Agbegbe eti omi Chad yii lo jẹ agbegbe kan ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbesunmọmi ti n ṣọṣẹ ti wọn si maa n gba owo ori lọwọ awọn apẹja, awọn to n ko igi atawọn darandaran.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Àmì ẹ̀yẹ Grammy 2026: Wo àwọn olórin tí wọ́n fà kalẹ̀

Àmì ẹ̀yẹ Grammy 2026: Wo àwọn olórin tí wọ́n fà kalẹ̀

Ọjọ́ Àìkú, 9 Oṣù Bélú 2025 ní 09:26:20

Awọn olorin bii Burna Boy, Wizkid ati Tyla, wa lara awọn ọmọ ilẹ Africa ti wọn fa kalẹ fun orin ilẹ Africa to dara julọ bayii.

Wo nǹkan márùn-un tó ti ṣẹlẹ̀ látìgbà tí Trump ti lóun yóò gbèjà àwọn Kristẹni ní Naijiria

Wo nǹkan márùn-un tó ti ṣẹlẹ̀ látìgbà tí Trump ti lóun yóò gbèjà àwọn Kristẹni ní Naijiria

Ọjọ́ Àìkú, 9 Oṣù Bélú 2025 ní 06:35:18

BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn kókó ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tó ti wáyé lẹ́yìn ìkéde Trump nípa Nàìjíríà.

Ṣé lóòótọ́ ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lu olùkọ́ pa ní ìlú Ogbomoso?

Ṣé lóòótọ́ ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lu olùkọ́ pa ní ìlú Ogbomoso?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 17:45:02

Àtẹ̀jáde kan tí ẹgbẹ́ olùkọ́, Nigeria Union of Teachers, NUT ẹ̀ka ìlú Ogbomoso fi sórí ayélujára sọ pé pẹ̀lú ọgbẹ́ ọkàn ni àwọn fi ń kẹ́dùn ikú ọ̀gbẹ́ni Adegoke tó pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lẹ́yìn táwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan lù ú bí ejò àìjẹ.

Àwọn ewu mẹ́fà tó wà nínú mímu sìgá olóoru oníbátìrì Vape

Àwọn ewu mẹ́fà tó wà nínú mímu sìgá olóoru oníbátìrì Vape

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 17:03:33

Adari ajọ WHO, Tedros Adhanom Ghebreyesus ti fẹun kan awọn ileeṣẹ to n ṣe siga pe wọn n mọọmọ n fa oju awọn ọmọde mọra lati maa fa siga.

Àwọn ìgbésẹ̀ tó yẹ kí Tinubu gbé rèé kí Trump má ba à ṣe ìkọlù sí Nàìjíríà - Pásítọ̀ Adeboye

Àwọn ìgbésẹ̀ tó yẹ kí Tinubu gbé rèé kí Trump má ba à ṣe ìkọlù sí Nàìjíríà - Pásítọ̀ Adeboye

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 15:33:30

Ó sọ pé ẹ̀mí àwọn èèyàn ṣe pàtàkì gidi, tó sì pàrọwà sí ìjọba àpapọ̀ láti fáwọn olórí ẹ̀ṣọ́ ààbò Nàìjíríà ní gbèdéke oṣù mẹ́ta láti fi ri pé àwọn agbéṣùmọ̀mí di ohun ìgbàgbé tàbí kí wọ́n pàdánù iṣẹ́ wọn.

Ṣé lóòótọ́ ni àwọn agbéṣùmọ̀mí bẹ́ orí alága CAN ti ìpínlẹ̀ Adamawa?

Ṣé lóòótọ́ ni àwọn agbéṣùmọ̀mí bẹ́ orí alága CAN ti ìpínlẹ̀ Adamawa?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 13:23:34

Agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ náà, Suleiman Yahaya Nguroje nínú àtẹ̀jáde kan tó fi léde lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, ọjọ́ Kẹjọ, oṣù Kọkànlá, ọdún 2025 júwe ìròyìn náà èyí tí ẹnìkan, Lionman Lioni gbé sórí ìkànnì Facebook rẹ̀ bí ọ̀nà láti dá ìjà ẹ̀sìn sílẹ̀.

‘Ilẹ̀ Owo ti di ibi àìgbọdọ̀ wọ̀ fún Alága káńsù tó tàbùkù Ọlọ́wọ̀’, ìgbìmọ̀ Ọlọ́wọ̀ fárígá

'Ilẹ̀ Owo ti di ibi àìgbọdọ̀ wọ̀ fún Alága káńsù tó tàbùkù Ọlọ́wọ̀', ìgbìmọ̀ Ọlọ́wọ̀ fárígá

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 11:45:33

Yatọ si pe wọn fi ọwọ osi juwe ile fun Alaga tẹlẹ naa, igbimọ ti a mọ si Olowo-In-Council tun sọ pe awọn eeyan ilu Owo paapaa ko fẹ ri Omolayo nipo alaga mọ.

Ọmọ orílẹ̀èdè Mexico joyè Gbáwoníyì ní Ekiti, ó ní àṣà Yoruba kò gbọdọ̀ parun

Ọmọ orílẹ̀èdè Mexico joyè Gbáwoníyì ní Ekiti, ó ní àṣà Yoruba kò gbọdọ̀ parun

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 10:20:12

Gomez jẹ ọmọ orilẹede Mexixo to fẹran aṣa ilẹ Yoruba to tun jẹ Babalawo.

Tọkọ taya tó dàgbà jùlọ lágbàáyé sọ ìrírí wọn lẹ́yìn tí ìgbéyàwó wọn pé ọdún 83

Tọkọ taya tó dàgbà jùlọ lágbàáyé sọ ìrírí wọn lẹ́yìn tí ìgbéyàwó wọn pé ọdún 83

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 8 Oṣù Bélú 2025 ní 06:43:24

Lyle ati Eleanor Gittens ti wọn jẹ akẹkọọ nile ẹkọ giga fasiti Clark Atlanta University pade ara wọn lọdun 1941 lọdun mẹrindinlelọgọrin sẹyin.

Kókó tó wà nínú èsì Tinubu sọ́rọ̀ tí Trump sọ nípa Naijiria lórí ẹ̀sùn ìṣekúpani àwọn Kristẹni

Kókó tó wà nínú èsì Tinubu sọ́rọ̀ tí Trump sọ nípa Naijiria lórí ẹ̀sùn ìṣekúpani àwọn Kristẹni

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 19:20:23

Igba akọkọ ree ti Aarẹ Tinubu yoo sọrọ lẹyin ti Aarẹ Amẹrika, Donald Trump dunkoko lati ko ogun wọ orilẹede Naijiria, lori ẹsun pe Kristẹni nikan ni awọn agbebọn n ṣekupa.

Ó ti di èèwọ̀ láti máa ta ọtí pẹlẹbẹ inú ọ̀rá ní Naijiria – Ilé aṣòfin

Ó ti di èèwọ̀ láti máa ta ọtí pẹlẹbẹ inú ọ̀rá ní Naijiria – Ilé aṣòfin

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 16:11:25

Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti aṣofin Asuquo Ekpeyong ni ijọba ko gbọdọ fun awọn to n ta ọti inu ọra naa laye mii mọ lati ko kuro nilẹ.

Ṣàǹgbáfọ́! Àwọn ọ̀dọ́bìnrin tí wọ́n fún òrìṣà gẹ́gẹ́bí ìyàwó nílùú ibìkan ti di olówò nọ̀bì!

Ṣàǹgbáfọ́! Àwọn ọ̀dọ́bìnrin tí wọ́n fún òrìṣà gẹ́gẹ́bí ìyàwó nílùú ibìkan ti di olówò nọ̀bì!

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 12:34:49

Lọdun 1982 ni ipinlẹ Karnataka fofin de aṣa yii, amọ, o si tẹsiwaju titi di oni.

Onídìrí ọmọ Naijiria di irun fún wákàtí 24, gba àmì ẹ̀yẹ Guinness World Records

Onídìrí ọmọ Naijiria di irun fún wákàtí 24, gba àmì ẹ̀yẹ Guinness World Records

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 11:52:49

Gẹgẹ bii GWR se sọ, Mary ti fẹran lati ma dirun lati igba to ti wa ni kekere, to si lero lati fi erongba rẹ fi ṣe aṣeyọri ni ọjọ Iwaju.

Kí ló dé tí ẹnu ń kun Obasa, olórí ilé aṣòfin Eko lórí ọmọ rẹ̀, Abdul-Ganiyu tó di Alága ìjọba ìbílẹ̀ Agege

Kí ló dé tí ẹnu ń kun Obasa, olórí ilé aṣòfin Eko lórí ọmọ rẹ̀, Abdul-Ganiyu tó di Alága ìjọba ìbílẹ̀ Agege

Ọjọ́ Ẹtì, 7 Oṣù Bélú 2025 ní 06:21:34

Lẹyin ti ile igbimọ aṣofin ijọba ibilẹ Agege tẹwọgba ikọwefipo silẹ Azeez, igbimọ naa yan Hon AbdulGaniyu Vinod Obasa gẹgẹ bii ẹni ti yoo rọpọ Azeez gẹgẹ bii alaga ijọba ibilẹ naa.

Paul Biya ṣèlérí láti gbógun tìwà ìbàjẹ́ lẹ́yìn ìbúrawọlé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ orílẹ́èdè Cameroon fún sáà kẹ́jọ

Paul Biya ṣèlérí láti gbógun tìwà ìbàjẹ́ lẹ́yìn ìbúrawọlé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ orílẹ́èdè Cameroon fún sáà kẹ́jọ

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 17:59:42

Paul Biya di aarẹ Cameroon loṣu Kọkanla ọdun 1982 lẹyin ti Aarẹ Ahmadou Ahidjo kọwe fipo silẹ.

Zohan Mamdani mùsùlùmí àkọ́kọ́ tí yóò jẹ alákòóso ìjọba New York sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Donald Trump

Zohan Mamdani mùsùlùmí àkọ́kọ́ tí yóò jẹ alákòóso ìjọba New York sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Donald Trump

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 15:13:23

Ni ilu Kampala,lorilẹede Uganda ni wọn ti bi Mamdani ki o to lọ si ilu New York pẹlu ẹbi rẹ nigba to jẹ ọmọ ọdun meje.

Ṣé lóòótọ́ ni wọ́n ń pa àwọn Kristẹni lọ́gọ̀ọ̀rọ̀ ní Nàìjíríà bí Trump ṣe fẹ̀sùn kàn?

Ṣé lóòótọ́ ni wọ́n ń pa àwọn Kristẹni lọ́gọ̀ọ̀rọ̀ ní Nàìjíríà bí Trump ṣe fẹ̀sùn kàn?

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 14:23:21

Láti bíi oṣù díẹ̀ sẹ́yìn ni àwọn olóṣèlú kan ní Washington ti ń fẹ̀sùn kàn pé àwọn alákatakítí ẹ̀sìn Islam ń mọ̀ọ́mọ̀ kojú oro sáwọn Kristẹni ní Nàìjíríà.

Kí làtunbọ̀tán àwọn orílẹ̀èdè méje tí Amẹ́ríkà ti kọ́mọ́ogun wọ̀ rí ní Áfíríkà?

Kí làtunbọ̀tán àwọn orílẹ̀èdè méje tí Amẹ́ríkà ti kọ́mọ́ogun wọ̀ rí ní Áfíríkà?

Ọjọ́rú, 5 Oṣù Bélú 2025 ní 15:38:04

Ijọba apapọ Naijiria ti sọ pe ko si nnkan to jọ ipanirun awọn kristẹni gẹgẹ bi Aarẹ Donald Trump Amẹrika ṣe sọ.

Ọkọ̀ rélùwéè kọlu kẹ̀kẹ́ Maruwa, òkú sùn

Ọkọ̀ rélùwéè kọlu kẹ̀kẹ́ Maruwa, òkú sùn

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 10:53:08

Bakan naa ni eeyan meji mi tun farapa yanayana lasiko ijamba naa.

Àwọn ọ̀dọ́ lu Ìmáàmù àgbà kan pa ní Kwara; Ohun tí a mọ̀ nípa rẹ̀ rèé

Àwọn ọ̀dọ́ lu Ìmáàmù àgbà kan pa  ní Kwara; Ohun tí a mọ̀ nípa rẹ̀ rèé

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 11:42:25

Gana ni wọn ni o sọ fun awọn eeyan pe ọpọ igba ni oun n ri imaamu agba naa loju ala to n kọlu oun.

‘Ńṣe ni gbogbo àwọ́ ara mi ń bó’ - Obìnrin Africa tí wọ́n fẹ̀tàn mù láti máa ṣe àdó olóró

'Ńṣe ni gbogbo àwọ́ ara mi ń bó' - Obìnrin Africa tí wọ́n fẹ̀tàn mù láti máa ṣe àdó olóró

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 05:29:29

Ìwádìí BBC ṣàfihàn bí wọ́n ṣe ń fi ẹ̀tàn jẹ́ kí àwọn obìnrin Africa máa pèsè àdó olóró ní Russia.

Ẹ̀sọ̀pẹ̀lẹ́ ló yẹ kóo fi dá sí ìpèníjà ààbò Nàìjíríà - Ìjọba àpapọ̀ rọ Trump

Ẹ̀sọ̀pẹ̀lẹ́ ló yẹ kóo fi dá sí ìpèníjà ààbò Nàìjíríà - Ìjọba àpapọ̀ rọ Trump

Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Bélú 2025 ní 09:25:22

Tinubu sọ pe ijọba n gbe igbesẹ lati pese aabo to peye fun araalu ati dukia ọmọ Naijiria.

Àjọ ECOWAS àti EU kéde àtìlẹ́yìn fún Naijiria lórí ọ̀rọ̀ tí Trump sọ, pè fún ìrànwọ́ láti kojú àwọn agbésùnmọ̀mí

Àjọ ECOWAS àti EU kéde àtìlẹ́yìn fún Naijiria lórí ọ̀rọ̀ tí Trump sọ, pè fún ìrànwọ́ láti kojú àwọn agbésùnmọ̀mí

Ọjọ́rú, 5 Oṣù Bélú 2025 ní 19:35:51

Mignot ni ajọ orilẹede Naijiria ati EU ti wa tipẹ, ti EU ko si ni tẹti si ọrọ miiran ti orilẹede mi ba sọ sita nipa Naijiria.