Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 15:38:37
Ọpọ eeyan kaakiri agbaye lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọ lede lori ofin tuntun yii. Bi awọn kan ṣe n bu ẹnu atẹ lu Trump lori ọfin naa lawọn mii n sọ pe ohun to tọ ni lasiko yii.
Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 13:21:33
Gbogbo awọn ẹlẹran ti a fọrọ wa lẹnu wo lo sọ wi pe ẹran wọn lọdun yii ju ọdun to kọja lọ.
Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:10:20
BBC Yoruba de Ijebu Ode, ti a si ba Ọgbeni Ọja tilẹ Ijebu, Olorogun Sunny Folorunso Kuku, tii se olori ẹbi Kuku sọrọ nipa itan aye baba nla rẹ, Balogun Kuku.
Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 13:06:56
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 05:33:15
Eleyii yii ti bẹrẹ lati ana ọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹta oṣu Kẹfa yii, lẹyin ti ajọ NCC to n ri si eto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria pa a laṣẹ fawọn banki lati maa ṣe bẹẹ.
Ọjọ́bọ, 5 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:48:04
Iye eeyan to ti padanu ẹmi wọn lori iṣẹlẹ yii lo ti le ni igba gẹgẹ bii ohun ti awọn alaṣẹ gbe sita.
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 14:25:00
Eyi ni ohun to sẹlẹ ni ile ẹjọ lonii lẹyin ti igbẹjọ naa bẹrẹ laago mẹsan kọja isẹju mẹfa ni ile ẹjọ giga ipinlẹ kwara labẹ adajọ Christiana Ajayi.
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 18:13:51
Ọmọwe Chris Bishop to jẹ onimọ nipa imọ ijinlẹ lori ikore oko ni fasiti Lincoln sọ pe ‘‘ewu to wa ninu anamọ to ti n hu ni kẹmika ti wọn n pe ni glycoalkaloids, eyi lo maa n jẹ ki iru anamọ bẹẹ koro lẹnu.
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 12:56:46
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́, níbi ètò kan tí wọ́n ti fẹ́ ṣe ìfilọ́lẹ̀ sísọ ọ̀nà Igbokoda sí Okitipupa di oníbejì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 15:06:37
Biola Adebayo sọ pe igbeyawo oun ti tuka
Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 08:26:18
Mọlẹbi to ni aisan Trichoepithelioma, aisan kan to ma n ran ninu ẹbi, ba BBC Yoruba sọrọ lori iriri wọn
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 09:01:06
Ìròyìn ní ọ̀pọ̀ èèyàn ló kú, táwọn míì sì farapa nígbà táwọn míì sá àsálà fún ẹ̀mí ara wọn.
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 05:50:03
Iroyin ni akẹkọọjade ilẹ ẹkọ Afe Babalola University, to wa niluu Ado Ekiti, (ABUAD) ni oloogbe ọhun, ko to maa kẹkọọ nipa imọ “cybersecurity” ni aja kẹjọ Cocoa House ṣaaju iṣẹlẹ laabi naa.
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 07:08:34
Olawole Olakunle, Babalawo to n jatọ ba BBC sọrọ lori ipa ti imọ ẹrọ n ko ibamu pẹlu Ifa ati awọn nnkan aṣa miiran.
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:52:41
Kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Wilfred Olutokunbo Afolabi sọrọ lori awọn aṣeyọri ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa, ati awọn ipenija wọn
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 16:16:49
Iṣẹlẹ omiyale yii ni igbagbọ wa pe oun lo buru ju lorilẹede Naijiria, laarin aadọta ọdun.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 16:26:44
Ileya jẹ́ ọdún tó ṣe pàtàkì sáwọn Mùsùlùmí nítorí òhun ni wọ́n kà kún ọdún ńlá níbi tí wọ́n ti máa ń pa ẹran àgbò.
Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 10:31:38
Ọmọ kan ṣoṣo naa ni Adamu ṣẹṣẹ bi, o ṣalaye fun BBC pe ọmọ ikoko naa pẹlu iya rẹ to bi i foun, wa lara awọn eeyan ti omi wọ lọ latari ojo nla to rọ l’Ọjọruu mọju Ọjọbọ, nipinlẹ Niger. Eyi to fa omiyale ati ẹkun omi to bo ori awọn ile lọ.
Ọjọ́rú, 4 Oṣù Òkúdu 2025 ní 10:32:17
Nàìjíríà ni orílẹ̀ èdè tó léwu jùlọ ní àgbáyé láti bímọ sí pẹ̀lú àkọ́ọ́lẹ̀ ìdá mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29%) àwọn obìnrin tó pàdánù ẹ̀mí wọn lásìkò ìbímọ káàkiri àgbáyé.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 09:58:04
Kíkọ nǹkan sílẹ̀ ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú ojú àti ẹ̀yà ara tó wà fún ara yíyí.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 05:47:42
Nibi ti kẹkẹ gbayi de lọdọ awọn obinrin Askira, dandan ni ki ọkunrin to ba fẹẹ fẹ wọn ra kẹkẹ mọ ẹru obinrin ti yoo gbe niyawo.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 06:15:55
Iwadii BBC YORUBA ṣafihan pe akẹkọọ naa, Elisha Wisdom n gbiyanju lati lo ẹrọ ilewọ rẹ lasiko ti ọgbẹni Rotifa gba ẹrọ ilewọ naa eyi to mu ki inu bi iya ọmọ ọhun gidigidi.
Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 07:03:54
Ko din ni aadọfa eeyan ti omi gbe lọ, ti ọpọ eeyan si di alainilelori lẹyin ti agbara ojo ya wọ ile wọn nipinlẹ Niger
Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 17:41:29
Àwọn aráàlú ní ìpínlẹ̀ náà sọ pé ogún èèyàn ló pàdánù ẹ̀mí wọn nígbà tí iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà fi ọkọ̀ òfurufú ju àdó olóró sí ìlú náà láti fi lásìkò tí wọ́n ń gbìyànjú láti kojú ìjà sáwọn agbébọn tó wà ṣe ìkọlù sí wọn.
Ọjọ́ Ajé, 2 Oṣù Òkúdu 2025 ní 08:58:00
Nigba to n ba BBC News Yorùbá sọrọ Aishat Tahiru sọ pe, lọjọ Kẹẹdọgbọn, osu Karun un ni oun tẹ ọmọ oun to jẹ ọmọ oṣu meji ti orukọ rẹ n jẹ Adam Tahiru sinu yara lati sun, ti oun si lọ kirun lẹyinkule.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 3 Oṣù Òkúdu 2025 ní 11:43:15
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, DSP Abiodun Ojelabi, ṣalaye fun BBC Yoruba wi pe awọn ẹlẹgbe okunkun lo ọdun egungun to waye lagbegbe Oke Ola niluu Osogbo lati ṣe ikọlu si ara wọn.
Ọjọ́ Àìkú, 1 Oṣù Òkúdu 2025 ní 17:55:31
Iroyin ni ṣẹ ni ọkunrin naa ṣeṣi yinbọn pa ọmọ rẹ ọhun to jẹ ọmọ ọdun marundinlogun latari bi awọn ọbọ ṣe maa n da a lamu ninu oko rẹ.
Ọjọ́ Àìkú, 1 Oṣù Òkúdu 2025 ní 10:43:15
Eeyan mọkanlelogun lo padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to waye lẹyin ti wọn kuro nipinlẹ Ogun.
Ọjọ́ Àìkú, 1 Oṣù Òkúdu 2025 ní 08:25:27
Tí obìnrin kò bá rí nǹkan oṣù rẹ̀ láàárín ọjọ́ péréte tàbí tí ọjọ́ tó yẹ kó ri bá lé díẹ̀, ó ṣeéṣe kó má jẹ̀ ẹ́ ohun tó nira àmọ́ tó bá ń léra ní gbogbo ìgbà, ó nílò àmójútó, ó sì lè jẹ́ àmì àpẹẹrẹ àìsàn kan tàbí òmíràn.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 16:49:41
Ileeṣẹ ọlọpaa ti sọ pe oun ko ni dẹkun ati maa wa ọmọde naa bo tilẹ jẹ pe awọn to ta ti gba idajọ to yẹ wọn.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 31 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:02:24
Àwọn kan gbàgbọ́ pé àwọn èròjà aṣaralóore wà nínú olubi ọmọ èyí tí ọmọ ń gbà lára ìyá rẹ̀ nínú oyún àti pé kò yẹ káwọn èròjà náà ṣòfò lẹ́yìn tí ọmọ bá dáyé tán.
Ọjọ́ Ẹtì, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 12:28:52
Regina Chukwu sọ pe ni kete ti oun pari ile ẹkọ girama ni oun pade ọkọ oun to jẹ ẹya Igbo nipinlẹ Anambra.
Ọjọ́ Ẹtì, 30 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 11:02:36
BBC Yoruba de ilu Omu Aran nipinlẹ Kwara lati bawọn se ọdun Orugbo ti ọdun yii, ti a si gbọ ẹkunrẹrẹ itan nipa igbe aye Iya agba Orugbo.