world-service-rss

BBC News Yorùbá

Àwọn èrò fò bọ́ sílẹ̀ láti ojú fèrèsé níbi ìjàmbá ọkọ̀ ojú irin tó gbẹ̀mí èèyàn 15

Àwọn èrò fò bọ́ sílẹ̀ láti ojú fèrèsé níbi ìjàmbá ọkọ̀ ojú irin tó gbẹ̀mí èèyàn 15

Ọjọ́bọ, 23 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:57:23

Iye èèyàn tó farapa níbi ìjàmbá kò ì tíì yé ṣùgbọ́n àwọn iléeṣẹ́ ìròyìn abẹ́lé ń sọ pé àwọn èèyàn tó farapa wà láàárín mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n sí mọ́kàndínlọ́gbọ̀n.

Gómìnà Adeleke yan Davido sípò aláàmójútó àṣùwọ̀n ẹ̀dáwó ìdàgbàsókè eré ìdárayá

Gómìnà Adeleke yan Davido sípò aláàmójútó àṣùwọ̀n ẹ̀dáwó ìdàgbàsókè eré ìdárayá

Ọjọ́bọ, 23 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 05:55:44

Igbakeji Gomina ipinlẹ Osun, Kola Adewusi, lo sọ eyi di mimọ nigba ti ẹgbẹ awọn akọroyin ere idaraya, ẹka ti ipinlẹ Osun, (SWAN) ṣe abẹwo si ọfisi rẹ.

Bó bá jẹ̀bi ẹ̀sùn fífipá bọ́mọdé lò pọ̀, gbére lẹ̀wọ̀n rẹ! Àwọn ìjìyà tuntun tí ilé aṣòfin àgbà buwọ́lù rèé

Bó bá jẹ̀bi ẹ̀sùn fífipá bọ́mọdé lò pọ̀, gbére lẹ̀wọ̀n rẹ! Àwọn ìjìyà tuntun tí ilé aṣòfin àgbà buwọ́lù rèé

Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 17:32:14

Ẹni to ba fipa ja abale eeyan ti wọn maa n dajọ ẹwọn ọdun marun un fun un tẹlẹ, yoo maa gba idajọ ẹwọn gbere bayii.

Ọkọ̀ mẹ́rin forí sọ ara wọn lójú pópó, èèyàn 46 jáde láyé

Ọkọ̀ mẹ́rin forí sọ ara wọn lójú pópó, èèyàn 46 jáde láyé

Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 13:42:21

Ọkọ mẹrin ọtọtọ lori fori sọra wọn ninu ijamba ọhun.

Ọmọ ọdún 17 yọ ojú àbúrò rẹ̀ obìnrin fi ṣe òògùn owó

Ọmọ ọdún 17 yọ ojú àbúrò rẹ̀ obìnrin fi ṣe òògùn owó

Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 14:08:27

Iṣẹlẹ ọhun to waye ni ọjọ kẹtadinlogun Oṣu Kẹwaa, sọ Rukayya Muhammad di ẹni ti ko le ri iran mọ.

Èèyàn tó lé ní 30 jóná kú níbi tí wọ́n ti ń gbọ́n epo níbi táńkà tó gbiná

Èèyàn tó lé ní 30 jóná kú níbi tí wọ́n ti ń gbọ́n epo níbi táńkà tó gbiná

Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 11:05:37

Alaye awọn eeyan ti ijamba naa ṣoju wọn ni pe bi tanka agbepo ọhun ṣe ṣubu ni awọn eeyan kan bẹrẹ si i gbọn epo to n danu.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo sọ̀rọ̀ lórí lẹ́tà DSS nípa ìkọlù tí ISWAP fẹ́ ṣe sí Owo àti Akoko

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo sọ̀rọ̀ lórí lẹ́tà DSS nípa ìkọlù tí ISWAP fẹ́ ṣe sí Owo àti Akoko

Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:55:16

Ti ẹ ko ba gbagbe, kii ṣe igba akọkọ ree ti agbesunmọmi yoo kọlu ilu Owo, ipinlẹ Ondo ti wọn yoo si gbẹmi ọpọ eeyan.

Kí ni ìdí tí Sultan Sokoto ṣe ń pè fún fífọwọ́ tó le mú àṣìlò ojú òpó ayélujára ní Nàìjíríà?

Kí ni ìdí tí Sultan Sokoto ṣe ń pè fún fífọwọ́ tó le mú àṣìlò ojú òpó ayélujára ní Nàìjíríà?

Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:10:54

Nigba to n sọrọ ni igbimọ awọn lọbalọba apa ariwa lọjọ Isẹgun ni Birnin Kebbi, Sultan kọninu lori bi ayederu iroyin ṣe n lọ kaakiri orilẹede ayelujara, ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria si ni lati tẹwọgba.

Taa ni Sanae Takaichi, olóṣèlú obìnrin bíi ọkunrin Japan?

Taa ni Sanae Takaichi, olóṣèlú obìnrin bíi ọkunrin Japan?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 17:35:28

Sanae Takaichi ti bori ibo lọjọ Iṣẹgun lati di olootu ijọba obinrin akọkọ ni Japan.

Kà nípa àwọn ìdìtẹ̀gbàjọba ológun tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria àti ìpa tó ní

Kà nípa àwọn ìdìtẹ̀gbàjọba ológun tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria àti ìpa tó ní

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:07:08

Latigba ti Naijiria ti gba ominira ni 1960 ni wọn ti n koju iditẹgbajọba.

Ṣé lóòòtọ́ọ́ ni ìjìyà wà fún ẹnikẹ́ni tó bá fún obìnrin lóyún láì ṣètọ́jú rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Eko? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ṣé lóòòtọ́ọ́ ni ìjìyà wà fún ẹnikẹ́ni tó bá fún obìnrin lóyún láì ṣètọ́jú rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Eko? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:52:49

Ewẹ, ijọba ipinlẹ Eko ti sọ pe iroyin ofege lo ni ìjọba ti ṣe agbekalẹ ofin ti yoo maa fiya jẹ ẹnikẹni to ba fun obinrin loyun lai ṣe itọju rẹ.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Wo ìlànà tuntun tí ìjọba là kalẹ̀ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó bá fẹ́ jàǹfàní ètò ẹ̀yáwó-kẹ́kọ̀ọ́ fún 2025/2026

Wo ìlànà tuntun tí ìjọba là kalẹ̀ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó bá fẹ́ jàǹfàní ètò ẹ̀yáwó-kẹ́kọ̀ọ́ fún 2025/2026

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 11:44:28

NELFUND sọ fun awọn akẹkọọ lati fi nọmba igbaniwọle wọn sile ẹkọ tabi nọmba iforukọsilẹ JAMB wọn lati fi orukọ silẹ loju opo rẹ.

Èwo nínú àwọn ẹ̀dùn ọkàn àwọn olúwọ́de #EndSARS lọ́dún 2020 n’ìjọba ti ṣe àmúṣẹ rẹ̀ lẹ́yìn ọdún márùn ún?

Èwo nínú àwọn ẹ̀dùn ọkàn àwọn olúwọ́de #EndSARS lọ́dún 2020 n'ìjọba ti ṣe àmúṣẹ rẹ̀ lẹ́yìn ọdún márùn ún?

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:00:16

Ṣáájú ìwọ́de náà ni onírúurú ẹ̀sùn ti ń wáyé nípa àwọn ọlọ́pàá SARS pé wọ́n ń ṣekúpa àwọn ọ̀dọ́ lọ́nà àìtọ́, tí wọ́n sì máa ń dá àwọn ọ̀dọ́ lọ́nà, gba gbogbo ìní tí wọ́n bá kó dání.

Kí nìdí táwọn èèyàn fi ń sọ pé Gómìnà Adeleke fẹ́ darapọ̀ mọ́ APC? Adeleke fúnrarẹ̀ ṣàlàyé

Kí nìdí táwọn èèyàn fi ń sọ pé Gómìnà Adeleke fẹ́ darapọ̀ mọ́ APC? Adeleke fúnrarẹ̀ ṣàlàyé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 08:59:39

Tẹ o ba gbagbe, awuyewuye nipa pe Gomina Adeleke fẹẹ kuro ni PDP, ko si darapọ mọ APC ko ṣẹṣẹ maa waye, iroyin naa ti kọkọ gbode bii oṣu meloo sẹyin.

Kí ló fa gbas-gbos láàárín Olowo ìlu Owo àti alága káńsù tí alága fi ń fi òkò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ sí Kábíyèsí?

Kí ló fa gbas-gbos láàárín Olowo ìlu Owo àti alága káńsù tí alága fi ń fi òkò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ sí Kábíyèsí?

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 13:37:00

Alága ìjọba ìbílẹ̀ Owo sọ̀rọ̀ àbùkù sí Olowo, àwọn ọmọ ilú fárígá.

Ọlọ́pàà yin tajútajú sáwọn olùwọ́de tó ń pè fún ìtúsílẹ̀ Nnamdi Kanu l’Abuja, ẹni orí yọ ó dilé

Ọlọ́pàà yin tajútajú sáwọn olùwọ́de tó ń pè fún ìtúsílẹ̀ Nnamdi Kanu l'Abuja, ẹni orí yọ ó dilé

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:14:11

Ajafẹtọọ ọmọniyan, Omoyele Sowore, lo ṣaaju awọn oluwọde naa bo tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ikilọ sita ṣaaju ifẹhonuhan ọhun.

Bàálù tó fẹ́ ba ṣekú pàwọn ẹ̀ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú nínú ọkọ̀ wọn, àwọn awakọ̀ bàálù mọ́ríbọ́

Bàálù tó fẹ́ ba ṣekú pàwọn ẹ̀ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú nínú ọkọ̀ wọn, àwọn awakọ̀ bàálù mọ́ríbọ́

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 09:22:17

Kete ti ijamba naa ṣẹlẹ lawọn mẹrin to wa ninu ọkọ ofurufu naa ṣi ilẹkun pajawiri lati sa asala fun ẹmi wọn.

Wo àwọn nǹkan mẹ́jọ tí kò tọ́ láti máa ṣe ní ẹ̀gbẹ́ gáàsì ìdáná

Wo àwọn nǹkan mẹ́jọ tí kò tọ́ láti máa ṣe ní ẹ̀gbẹ́ gáàsì ìdáná

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:39:06

Lílo gáàsì gba ẹ̀sọ̀ nítorí gáàsì, tí èèyàn kò bá kíyèsí ara pẹ̀lú rẹ̀, ó le ṣokùnfà ìbúgbàmù ìjàmbá iná èyí ló le fa ṣíṣe òfò ẹ̀mí àti dúkìá.

Nnamdi Kanu : Ọlọ́pàá gbé ìkìlọ̀ kalẹ̀ lóríi ṣíse ìwọ́de nítòsí Aso Rock, Sowore fárígá

Nnamdi Kanu : Ọlọ́pàá gbé ìkìlọ̀ kalẹ̀ lóríi ṣíse ìwọ́de nítòsí Aso Rock, Sowore fárígá

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:14:39

Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Benjamin Hundeyin, ninu atẹjade to fi sita, ni ileeṣẹ ọlọpaa yoo ri pe mojuto ofin Naijiria to faye gba alaafia lasiko iwọde yii.

Kí ló fà á tí àwọn ọkùnrin fi máa ń lá àlá ìbálòpọ̀?

Kí ló fà á tí àwọn ọkùnrin fi máa ń lá àlá ìbálòpọ̀?

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 15:07:28

Titọ atọ fun ọkunrun lasiko to n ba sun lọwọ ko ki n ṣe nnkan to buru, gẹgẹ bii awọn onimọ ilera ṣe ṣalaye.

Kí ló ṣẹlẹ̀ láàárín Ned Nwoko àti Regina Daniels? Ohun tá a mọ̀ rèé

Kí ló ṣẹlẹ̀ láàárín Ned Nwoko àti Regina Daniels? Ohun tá a mọ̀ rèé

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:59:45

Nwoko, ninu ọrọ to gbe sori ayelujara fẹsun kan iyawo rẹ pe o n lo ogun oloro, ti oun si fẹ ri daju pe o tẹsiwaju ninu itọju rẹ nitori ẹru abo rẹ n ba oun.

Kà nípa àwọn ìdìtẹ̀gbàjọba ológun tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria àti ìpa tó ní

Kà nípa àwọn ìdìtẹ̀gbàjọba ológun tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria àti ìpa tó ní

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:07:08

Latigba ti Naijiria ti gba ominira ni 1960 ni wọn ti n koju iditẹgbajọba.

Púpọ̀ nínú ọọ́físì ìjọba ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo ló ti dagẹgẹ, Makinde gbọdọ̀ ṣe àtúnṣe si – Àwọn àṣofin

Púpọ̀ nínú ọọ́físì ìjọba ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo ló ti dagẹgẹ, Makinde gbọdọ̀ ṣe àtúnṣe si – Àwọn àṣofin

Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:52:14

Wọn ni ki Makinde ṣe atunṣe awọn ọọfisi naa ki iṣẹ awọn oṣiṣẹ rẹ le maa lọ dede.

Ìdí rèé tí Tinubu yóò fi lulẹ̀ nínú ìbò ààrẹ ọdún 2027 - Aregbesola

Ìdí rèé tí Tinubu yóò fi lulẹ̀ nínú ìbò ààrẹ ọdún 2027 - Aregbesola

Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 08:06:22

Aregbesola fidi ọrọ yii mulẹ nigba to n bawọn akọroyin sọrọ nibi ayẹyẹ ṣiṣi ọfiisi ẹgbẹ oṣelu ADC niluu Ilorin nipinlẹ Kwara lọjọ Aabamẹta ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹwaa yii.

Ohun tá a mọ̀ nípa ìkọlù àwọn agbébọn tó ṣekúpa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Kaduna

Ohun tá a mọ̀ nípa ìkọlù àwọn agbébọn tó ṣekúpa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Kaduna

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 18:12:23

Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kaduna fi di iṣẹlẹ naa mulẹ ṣugbọn ni eeyan meje lo padanu ẹmi, ti eeyan marun si farapa.

Wo àwọn àǹfààní tí irú ń ṣe fún ara

Wo àwọn àǹfààní tí irú ń ṣe fún ara

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:21:40

BBC ṣe ìwádìí nípa ọ̀pọ̀ àwọn àǹfààní tó wà nínú irú tí ẹ kò kà sí.

Wo bí àwọn hòmóònù tó wà nínú àgọ́ ara rẹ ṣe le dárí ìhùwàsí rẹ

Wo bí àwọn hòmóònù tó wà nínú àgọ́ ara rẹ ṣe le dárí ìhùwàsí rẹ

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:19:42

Àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì, láti ọjọ́ pípẹ́ ti mọ̀ pé àwọn kẹ́míkà kan tí wọ́n ń pè ní neurotransmiiters ní ipa tó lágbára lórí ọpọlọ èèyàn. Síbẹ̀, bí ìwádìí ṣe ń tẹ̀síwájú, wọ́n ń ṣàwárí rẹ̀ pé àwọn hòmóònù le ní ipa lórí wa lọ́nà tí a kò rokàn.

Àwọn wo ni àgbà amòfin márùn-ún tí Olubadan Ladoja gba láti gbógun ti àwọn ajagungbalẹ̀ n’Ibadan?

Àwọn wo ni àgbà amòfin márùn-ún tí Olubadan Ladoja gba láti gbógun ti àwọn ajagungbalẹ̀ n'Ibadan?

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:00:22

Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni Olubadan gbe igbesẹ naa, gẹgẹ bi Akọwe iroyin rẹ, Adebola Oloko, ṣe kede ninu atẹjade to fi sita l’Ọjọru.

Ìwádìí ìjìnlẹ̀ ṣàwarí ọmọdé tí wọ́n gbàgbé sí abẹ́ ilẹ̀ fún ọdún mẹ́jọ

Ìwádìí ìjìnlẹ̀ ṣàwarí ọmọdé tí wọ́n gbàgbé sí abẹ́ ilẹ̀ fún ọdún mẹ́jọ

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:04:07

Ara rẹ, ti wọn rii ni ilẹ asalẹ kan ni ita ile-ilẹ kan lori Fitzhamon Embankment, ti wọn ko si le fi idi iku rẹ mulẹ.

Ẹ wo ànfààní márùn ún tí Atailẹ̀ ń ṣe fún àgọ́ ara

Ẹ wo ànfààní márùn ún tí Atailẹ̀ ń ṣe fún àgọ́ ara

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:51:34

Fun apẹẹrẹ, Atailẹ ni eroja to n ba awọn Kokoro aifojuri ja, o maa n gbogun ti awọn aisan to wọpọ ati Kokoro kekeke to maa n fa ikọ, ọfinkin atawọn aidape ara miran

Ṣọ́jà la ìbọn mọ́ awakọ̀ kan lórí l’Ondo tó fi kú, iléeṣẹ́ ológun ṣàlàyé bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé

Ṣọ́jà la ìbọn mọ́ awakọ̀ kan lórí l'Ondo tó fi kú, iléeṣẹ́ ológun ṣàlàyé bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 05:32:39

Bo tilẹ jẹ pe wọn ko darukọ ṣọja ọhun, atẹjade ti Igbakeji adari ikede nileeṣẹ ologun, ẹka 32 Artillery Brigade, Major Njoka Irabor, fi sita l’Ọjọbọ oni, leri lati ri i pe ṣọja naa ko lọ lai jiya.

Hajj 2026: Ìdí rèé tí ìjọba Saudi ṣe mú àdínkù bá iye ọmọ Naijiria tí yòó lọ Hajj lọ́dún tó n bọ̀

Hajj 2026: Ìdí rèé tí ìjọba Saudi ṣe mú àdínkù bá iye ọmọ Naijiria tí yòó lọ Hajj lọ́dún tó n bọ̀

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 11:57:36

Atẹjade kan ti ajọ to n ri si irinajo Hajj ni Naijiria, National Hajj Commission of Nigeria (NAHCON) fi sita l’Ọjọbọ ana, lo kede adinku naa.

Èèyàn mẹ́ta bá òkú olóòtù ìjọba tẹ́lẹ̀ ní Kenya rìn lọ sọ́run bí ọlọ́pàá ṣe yìnbọn àti afẹ́fẹ́ tajútajú sọ́pọ̀ èrò tó ń kí òkú ọ̀hún káàbọ̀

Èèyàn mẹ́ta bá òkú olóòtù ìjọba tẹ́lẹ̀ ní Kenya rìn lọ sọ́run bí ọlọ́pàá ṣe yìnbọn àti afẹ́fẹ́ tajútajú sọ́pọ̀ èrò tó ń kí òkú ọ̀hún káàbọ̀

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 08:42:42

Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle mii jabọ pe eeyan mii tun ku, eyii to sọ apapọ gbogbo awọn to jade laye di mẹrin lasiko ti ọlọpaa n tu awọn ọgọrọ ero ọhun ka.

Ara Nnamdi Kanu le láti máa jẹ́jọ́ - Àbọ̀ ìwádìí àwọn dókítà sọ

Ara Nnamdi Kanu le láti máa jẹ́jọ́ - Àbọ̀ ìwádìí àwọn dókítà sọ

Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 10:55:52

Gẹ́gẹ́ àbọ̀ ìwádìí tí ẹgbẹ́ àwọn dókítà ilẹ̀ Nàìjíríà, NMA ṣe, wọ́n ní ìwádìí náà fi hàn pé àìsàn tó ń ṣe Kanu kìí ṣe èyí tó le la ẹ̀mí lọ àti pé ilé ìwòsàn tó wà ní ọgbà àwọn DSS tí Nnamdi Kanu wà le ṣe ìtọ́jú rẹ̀.