
Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 19:44:28
Ninu lẹta ti Tinubu fi ṣọwọ si aarẹ ile aṣofin agba l’Abuja, Sẹnẹtọ Godswill Akpabio, fun ibuwọlu ni aarẹ ti ṣalaye pe Musa ni yoo rọpo Alhaji Mohammed Badaru Abubakar minisita eto aabo tẹlẹ to kọwe fipo silẹ lọjọ Aje.

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:08:30
Igbesẹ tuntun yii ni yoo wọgile eyi to ti wa ni ilẹ tẹlẹ, to fun awọn araalu ni anfani lati gba owo toto milọnu marun un sita lọsẹ, ti awọn ileeṣẹ si le gba milọnu mẹwaa sita.

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 12:13:02
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:39:44
Oloye Olalekan Ogunmoyede, ẹni to jẹ olori awọn afọbajẹ iluu Igbajọ ba BBC news Yoruba sọrọ lori awọ to da rogbodiyan silẹ niluu naa.

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 07:41:08
Akọwe ijọba, Marco Rubio ni pe ile ijọba Washington n gbe igbesẹ yii lori aṣẹ Aarẹ Trump lati gbe ogun ti awọn eeyan kan ti wọn lọwọ ninu kiko ogun ja ati iṣekupani awọn Kristẹni ni Naijiria ati kaakiri agbaye.”

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:54:42
Ìjọba Australia ní ìgbésẹ̀ fífi òfin de àwọn ojú òpó yìí, èyí tí ọ̀pọ̀ àwọn obí faramọ́, jẹ́ ojúnà láti mú àdínkù bá ìpèníjà táwọn ọmọdé ń kojú lójú òpó ayélujára

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:22:44
Natasha ti ifẹ oun ati Tuface gbode lojiji, ni aṣofin to n ṣoju ẹkun Egor, nipinlẹ Edo.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:53:23
Ko tan si bẹ o, ṣe ni wọn tun fun ilu naa ni gbendeke ọsẹ kan lati san owo yii tabi ki wọn pa gbogbo awọn ti wọn ji gbe.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:30:05
Ọpọ awọn olugbe ijọba ibilẹ mẹfa ni ilu Ibadan, olu ilu Ipinlẹ Oyo ni wọn fi ehonu han loni ọjọ Aje ọjọ kẹwaa oṣu kọkonla ọdun 2025 lori bi ijọba Ipinlẹ Oyo se n wo dukia won lulẹ.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:16:30
Brian Mast to n ri sọrọ ilẹ okeere sọ pe ko si nnkan to jọ ija ileto kan si omiran ninu nnkan to n ṣẹlẹ ni Naijiria bayii, Mast ni awọn to n ṣe ikọlu yii mọọmọ fẹ pawọn kristẹni run lori ilẹ ati nile wọn ni.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 12:58:06
Ile ẹjọ giga kan niluu Abuja ti sọ pe oun yoo wọgile beeli to fun Omoyele Sowore to ba tun pada sọ ọrọ ti wọn gbagbọ pe o le da omi alaafia Naijiria ru.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:52:57
Irọlẹ oni, ọjọ Aiku, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kọkanla ọdun 2025 ni Aarẹ Tinubu kede bẹẹ loju opo X rẹ.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:54:42
Ìjọba Australia ní ìgbésẹ̀ fífi òfin de àwọn ojú òpó yìí, èyí tí ọ̀pọ̀ àwọn obí faramọ́, jẹ́ ojúnà láti mú àdínkù bá ìpèníjà táwọn ọmọdé ń kojú lójú òpó ayélujára

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:33:53
Gomina Ademola Adeleke ko tii kede ẹgbẹ oṣelu ti yoo darapọ mọ bayii, lẹyin to fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:45:47
Mathew Ekele ni ọwọ tẹ niluu Ogbese to wa loju ọna marosẹ ilu Akure siluu Owo.

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 07:27:25
Bẹẹ ba gbagbe, ẹgbẹ oṣelu PDP, lọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kọkanla lasiko ipade apero, fọwọ osi juwe ile fun Wike ati awọn yooku lori ẹsun pe wọn n ditẹ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:05:48
Anicet Ekane to ku si ahamọ yii jẹ ọkan lara awọn to ṣe atileyin fun Issa Tchiroma Bakary, alatako Aarẹ Paul Biya, ninu ibo to wa ye loṣu Kẹwaa ọdun yii.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:18:04
Ilé ẹjọ́ tún ṣe ìdádúró àwọn aláṣẹ fìdíẹ́ tí Ọba Ghandi yàn láti yé pe ara wọn ní aláṣẹ ẹgbẹ́ náà títí tí ìgbẹ́jọ́ fi máa wáyé ní oṣù Kìíní ọdún 2026.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 14:27:10
Eni ọdun mẹtadinlaadọrun ni Ọba Famodun ko to jade laye.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:33:53
Gomina Ademola Adeleke ko tii kede ẹgbẹ oṣelu ti yoo darapọ mọ bayii, lẹyin to fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 19:44:28
Ninu lẹta ti Tinubu fi ṣọwọ si aarẹ ile aṣofin agba l’Abuja, Sẹnẹtọ Godswill Akpabio, fun ibuwọlu ni aarẹ ti ṣalaye pe Musa ni yoo rọpo Alhaji Mohammed Badaru Abubakar minisita eto aabo tẹlẹ to kọwe fipo silẹ lọjọ Aje.

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 06:14:42
Bishop ni niṣe loun n gbọn nigba ti wọn ni koun wa jẹrii nile ẹjọ tori nnkan ti ko ṣẹlẹ ni wọn sọ pe koun maa sọ.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:19:58
Ninu lẹta kan ti minisita to n ri si ọrọ ilẹ okeere, Yusuf Tuggar, buwọlu, eyii to fi ṣọwọ si Aarẹ ẹgbẹ Ecowas, Omar Touray, Tuggar ni Aarẹ Naijiria ti paṣe pe ki wọn gbalejo ọkunrin naa ni ọọfisi ijọba Naijiria to wa lorilẹede naa, ki wọn si tun daabo bo nibẹ.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:36:31
Ipade naa ti awọn ori ade agbegbe naa yọju si ni wọn ti fẹnuko pe ki wọn maa ko owo ti iye rẹ to biliọnu kan naira jọ loṣoṣu fun eto abo agbegbe naa.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 08:19:54
Iwadii kan ti fi han pe bi eeyan ṣe n bi ọmọ si le maa yọ oṣu mẹfa lara obinrin.

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 06:06:37
Orilẹede Naijiria n koju oniruuru ipenija lọwọ yii latari oriṣiiriṣii ikọlu tawọn janduku agbebọn n ṣe kaakiri papaa julọ lẹkun ariwa orilẹede yii.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 14:15:36
Ni ana ọjọ Aiku ni iṣẹlẹ yii waye ni ilu naa, o si jẹ ẹlẹẹkeji iru ẹ ninu osu Kọkanla ọdun yii.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 07:54:11
Ṣiṣe odẹ tata ti wọn maa n pe ni Mungwin ni ede Cameroon jẹ nnkan to ti di aṣa nilẹ naa, o si jẹ ọrọ aje fun ọpọ eeyan níbẹ.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:16:48
Ọpọ lo n sọ pe Aarẹ Tinubu fi orukọ awọn eeyan naa ranṣẹ lati san oore ti wọn ṣe fun un lọna kan tabi ikeji pada ni.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:37:07
Nnkan bi ago mẹsan an abọ owurọ ọjọ Satide ni iṣẹlẹ naa waye lasiko ti Oba, Ojibara ti ilu Bayangan, Alhaji Kamilu Salami n lọ sinu oko rẹ.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:08:27
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpee ipinlẹ naa, DSP Ahmad Rufa’i, to fidi iroyin naa mulẹ fun ileeṣẹ iroyin Channels ni awọn ti gbe igbesẹ lọri ikọlu ọhun.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:42:49
Lati ọdun méjọ ti awọn mejeji fẹ ara wọn l’Amẹrika ni wọn pinnu lati wa si Naijiria.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:32:24
Obasanjo fi aidunnu rẹ lori bi eto aabo ṣe n buru sii ni Nàìjíríà, ààrẹ Naijiria tẹlẹ ni awọn ọmọ Naijiria lẹtọọ lati bèèrè iranwọ ilẹ okeere lẹyìn tí ìjọba ti kuna lati daabo bo araalu.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 12:01:00
BBC Yoruba kan si awọn oníṣẹṣe Yoruba lati mọ boya lootọ ni ayẹta wa, ta le lo pese ayẹta ati idi to fi le kùnà.

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 04:31:03
WHO ní ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́ tí àwọn lọ́kọláya tó bá ń kojú ìṣòro àìrí ọmọ bí nílò láti ṣe ni lílọ sí ilé ìwòsàn fún àyẹ̀wò tó péye.

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 17:05:53
A gbọ wi pe ṣadeedee lawọn janduku agbebọn ọhun ya wọ ṣoọṣi C & S naa ti wọn si bẹrẹ sii yinbọn lera lera.

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 11:03:20
Arsenal ti bori ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ninu meje ti wọn ti gba ni ligi, ti Chelsea si ti bori marun ninu mẹfa.

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 10:52:50
Eyi waye ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ologun fi lede loju opo ayelujara wọn lọgbọn ọjọ oṣu kọkanla ọdun 2025.

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 09:05:27
Ogun aarin awọn mejeji bẹrẹ lẹyin ti Hamas gbẹmi awọn ọmọ Israle lọjọ keje, oṣu Kẹwaa, ọdun 2023.