Ọjọ́bọ, 23 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:57:23
Iye èèyàn tó farapa níbi ìjàmbá kò ì tíì yé ṣùgbọ́n àwọn iléeṣẹ́ ìròyìn abẹ́lé ń sọ pé àwọn èèyàn tó farapa wà láàárín mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n sí mọ́kàndínlọ́gbọ̀n.
Ọjọ́bọ, 23 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 05:55:44
Igbakeji Gomina ipinlẹ Osun, Kola Adewusi, lo sọ eyi di mimọ nigba ti ẹgbẹ awọn akọroyin ere idaraya, ẹka ti ipinlẹ Osun, (SWAN) ṣe abẹwo si ọfisi rẹ.
Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 17:32:14
Ẹni to ba fipa ja abale eeyan ti wọn maa n dajọ ẹwọn ọdun marun un fun un tẹlẹ, yoo maa gba idajọ ẹwọn gbere bayii.
Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 13:42:21
Ọkọ mẹrin ọtọtọ lori fori sọra wọn ninu ijamba ọhun.
Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 14:08:27
Iṣẹlẹ ọhun to waye ni ọjọ kẹtadinlogun Oṣu Kẹwaa, sọ Rukayya Muhammad di ẹni ti ko le ri iran mọ.
Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 11:05:37
Alaye awọn eeyan ti ijamba naa ṣoju wọn ni pe bi tanka agbepo ọhun ṣe ṣubu ni awọn eeyan kan bẹrẹ si i gbọn epo to n danu.
Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:55:16
Ti ẹ ko ba gbagbe, kii ṣe igba akọkọ ree ti agbesunmọmi yoo kọlu ilu Owo, ipinlẹ Ondo ti wọn yoo si gbẹmi ọpọ eeyan.
Ọjọ́rú, 22 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:10:54
Nigba to n sọrọ ni igbimọ awọn lọbalọba apa ariwa lọjọ Isẹgun ni Birnin Kebbi, Sultan kọninu lori bi ayederu iroyin ṣe n lọ kaakiri orilẹede ayelujara, ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria si ni lati tẹwọgba.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 17:35:28
Sanae Takaichi ti bori ibo lọjọ Iṣẹgun lati di olootu ijọba obinrin akọkọ ni Japan.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:07:08
Latigba ti Naijiria ti gba ominira ni 1960 ni wọn ti n koju iditẹgbajọba.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:52:49
Ewẹ, ijọba ipinlẹ Eko ti sọ pe iroyin ofege lo ni ìjọba ti ṣe agbekalẹ ofin ti yoo maa fiya jẹ ẹnikẹni to ba fun obinrin loyun lai ṣe itọju rẹ.
Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 11:44:28
NELFUND sọ fun awọn akẹkọọ lati fi nọmba igbaniwọle wọn sile ẹkọ tabi nọmba iforukọsilẹ JAMB wọn lati fi orukọ silẹ loju opo rẹ.
Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:00:16
Ṣáájú ìwọ́de náà ni onírúurú ẹ̀sùn ti ń wáyé nípa àwọn ọlọ́pàá SARS pé wọ́n ń ṣekúpa àwọn ọ̀dọ́ lọ́nà àìtọ́, tí wọ́n sì máa ń dá àwọn ọ̀dọ́ lọ́nà, gba gbogbo ìní tí wọ́n bá kó dání.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 08:59:39
Tẹ o ba gbagbe, awuyewuye nipa pe Gomina Adeleke fẹẹ kuro ni PDP, ko si darapọ mọ APC ko ṣẹṣẹ maa waye, iroyin naa ti kọkọ gbode bii oṣu meloo sẹyin.
Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 13:37:00
Alága ìjọba ìbílẹ̀ Owo sọ̀rọ̀ àbùkù sí Olowo, àwọn ọmọ ilú fárígá.
Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:14:11
Ajafẹtọọ ọmọniyan, Omoyele Sowore, lo ṣaaju awọn oluwọde naa bo tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ikilọ sita ṣaaju ifẹhonuhan ọhun.
Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 09:22:17
Kete ti ijamba naa ṣẹlẹ lawọn mẹrin to wa ninu ọkọ ofurufu naa ṣi ilẹkun pajawiri lati sa asala fun ẹmi wọn.
Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:39:06
Lílo gáàsì gba ẹ̀sọ̀ nítorí gáàsì, tí èèyàn kò bá kíyèsí ara pẹ̀lú rẹ̀, ó le ṣokùnfà ìbúgbàmù ìjàmbá iná èyí ló le fa ṣíṣe òfò ẹ̀mí àti dúkìá.
Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:14:39
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Benjamin Hundeyin, ninu atẹjade to fi sita, ni ileeṣẹ ọlọpaa yoo ri pe mojuto ofin Naijiria to faye gba alaafia lasiko iwọde yii.
Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 15:07:28
Titọ atọ fun ọkunrun lasiko to n ba sun lọwọ ko ki n ṣe nnkan to buru, gẹgẹ bii awọn onimọ ilera ṣe ṣalaye.
Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:59:45
Nwoko, ninu ọrọ to gbe sori ayelujara fẹsun kan iyawo rẹ pe o n lo ogun oloro, ti oun si fẹ ri daju pe o tẹsiwaju ninu itọju rẹ nitori ẹru abo rẹ n ba oun.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 21 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:07:08
Latigba ti Naijiria ti gba ominira ni 1960 ni wọn ti n koju iditẹgbajọba.
Ọjọ́ Ajé, 20 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 16:52:14
Wọn ni ki Makinde ṣe atunṣe awọn ọọfisi naa ki iṣẹ awọn oṣiṣẹ rẹ le maa lọ dede.
Ọjọ́ Àìkú, 19 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 08:06:22
Aregbesola fidi ọrọ yii mulẹ nigba to n bawọn akọroyin sọrọ nibi ayẹyẹ ṣiṣi ọfiisi ẹgbẹ oṣelu ADC niluu Ilorin nipinlẹ Kwara lọjọ Aabamẹta ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹwaa yii.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 18:12:23
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kaduna fi di iṣẹlẹ naa mulẹ ṣugbọn ni eeyan meje lo padanu ẹmi, ti eeyan marun si farapa.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:21:40
BBC ṣe ìwádìí nípa ọ̀pọ̀ àwọn àǹfààní tó wà nínú irú tí ẹ kò kà sí.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:19:42
Àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì, láti ọjọ́ pípẹ́ ti mọ̀ pé àwọn kẹ́míkà kan tí wọ́n ń pè ní neurotransmiiters ní ipa tó lágbára lórí ọpọlọ èèyàn. Síbẹ̀, bí ìwádìí ṣe ń tẹ̀síwájú, wọ́n ń ṣàwárí rẹ̀ pé àwọn hòmóònù le ní ipa lórí wa lọ́nà tí a kò rokàn.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 07:00:22
Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni Olubadan gbe igbesẹ naa, gẹgẹ bi Akọwe iroyin rẹ, Adebola Oloko, ṣe kede ninu atẹjade to fi sita l’Ọjọru.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 06:04:07
Ara rẹ, ti wọn rii ni ilẹ asalẹ kan ni ita ile-ilẹ kan lori Fitzhamon Embankment, ti wọn ko si le fi idi iku rẹ mulẹ.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 12:51:34
Fun apẹẹrẹ, Atailẹ ni eroja to n ba awọn Kokoro aifojuri ja, o maa n gbogun ti awọn aisan to wọpọ ati Kokoro kekeke to maa n fa ikọ, ọfinkin atawọn aidape ara miran
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 18 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 05:32:39
Bo tilẹ jẹ pe wọn ko darukọ ṣọja ọhun, atẹjade ti Igbakeji adari ikede nileeṣẹ ologun, ẹka 32 Artillery Brigade, Major Njoka Irabor, fi sita l’Ọjọbọ oni, leri lati ri i pe ṣọja naa ko lọ lai jiya.
Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 11:57:36
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si irinajo Hajj ni Naijiria, National Hajj Commission of Nigeria (NAHCON) fi sita l’Ọjọbọ ana, lo kede adinku naa.
Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 08:42:42
Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle mii jabọ pe eeyan mii tun ku, eyii to sọ apapọ gbogbo awọn to jade laye di mẹrin lasiko ti ọlọpaa n tu awọn ọgọrọ ero ọhun ka.
Ọjọ́ Ẹtì, 17 Oṣù Ọ̀wàrà 2025 ní 10:55:52
Gẹ́gẹ́ àbọ̀ ìwádìí tí ẹgbẹ́ àwọn dókítà ilẹ̀ Nàìjíríà, NMA ṣe, wọ́n ní ìwádìí náà fi hàn pé àìsàn tó ń ṣe Kanu kìí ṣe èyí tó le la ẹ̀mí lọ àti pé ilé ìwòsàn tó wà ní ọgbà àwọn DSS tí Nnamdi Kanu wà le ṣe ìtọ́jú rẹ̀.