world-service-rss

BBC News Yorùbá

Tinubu kò dẹ́yẹ sí ẹkùn àríwá, onírúurú àkànṣe iṣẹ́ ló ń ṣe níbẹ̀, iléeṣẹ́ ààrẹ dáa padà fún Kwankwaso

Tinubu kò dẹ́yẹ sí ẹkùn àríwá, onírúurú àkànṣe iṣẹ́ ló ń ṣe níbẹ̀, iléeṣẹ́ ààrẹ dáa padà fún Kwankwaso

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 06:14:29

Oludamọran aarẹ lori ọrọ iroyin, Sunday Dare, sọ loju opo X rẹ pe irọ to jina sootọ ni gbogbo nnkan ti Kwankwaso sọ.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo fagilé ọjà títà lọjọ́ Àìkú lọ́ja Gbagi Ibadan laráàlú bá ń béèrè ìdí rẹ̀

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo fagilé ọjà títà lọjọ́ Àìkú lọ́ja Gbagi Ibadan laráàlú bá ń béèrè ìdí rẹ̀

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 26 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 10:01:40

Atẹjade naa ṣalaye, pe o ti di eewọ lati naja ni Gbagi ni Sannde, bẹẹ ni ijọba yoo fi kele ofin gbe ẹni to ba tapa si ofin yii.

Àwọn jàndùkú agbébọn pa tọkọ taya àti èèyàn mẹ́ẹ̀dógún míì, ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí

Àwọn jàndùkú agbébọn pa tọkọ taya àti èèyàn mẹ́ẹ̀dógún míì, ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 26 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 05:18:16

Ogbu Chidozie to ba BBC Igbo sọrọ ṣalaye pe eeyan mẹsan an to fi mọ ẹgbọn oun ati ọkọ rẹ ni wọn yinbọn pa ni Umualaoma ti i ṣe abule awọn.

Àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn kò tó ogún ọdún léwájú ìwọ́de tako ìjọba ọlọ́dún gbọọrọ ní Togo

Àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn kò tó ogún ọdún léwájú ìwọ́de tako ìjọba ọlọ́dún gbọọrọ ní Togo

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 26 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 07:09:48

Eredi iwọde naa ni lati tako ijọba Aarẹ Faure Gnassingbé, ẹni to ti fẹrẹ pe ọgọta ọdun ti idile rẹ ti n ṣejọba Togo.

Kókó tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá WAFCON láàrin Super Falcons àti Morocco lónìí

Kókó tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá WAFCON láàrin Super Falcons àti Morocco lónìí

Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 26 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 05:17:57

Super Falcons ti wọn ti gba ife ẹyẹ naa fun igba mẹsan an ọtọọtọ fẹ lu Morocco lati gba ife naa fun igba kẹwaa.

Mọ̀ nípa àwọn akọni obìnrin ọmọ Yorùbá tí òkìkí wọn kàn káàkiri àgbáyé

Mọ̀ nípa àwọn akọni obìnrin ọmọ Yorùbá tí òkìkí wọn kàn káàkiri àgbáyé

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 14:30:56

Lagbaaye loni, bi awọn ọkunrin to lorukọ ati okiki ṣe n gbayi nipasẹ ohun ti wọn n ṣe to n kun aye loju, bẹẹ ni awọn obinrin naa wa bẹẹ.

Àwọn nǹkan tí Hulk Hogan ṣe nígbà ayé rẹ̀ tó fa awuyewuye

Àwọn nǹkan tí Hulk Hogan ṣe nígbà ayé rẹ̀ tó fa awuyewuye

Ọjọ́bọ, 24 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 17:42:30

Lọdun 2015 ni wọn yọ Hulk Hogan kuro ninu ẹgbẹ ogbontarigi WWE Hall of Fame lori ẹsun pe o sọrọ kan to ni i ṣe pẹlu idẹyẹsi si ẹya mii.

Ohun tó yẹ kí o ṣe bí nǹkan bá sá pá ọmọ rẹ lórí?

Ohun tó yẹ kí o ṣe bí nǹkan bá sá pá ọmọ rẹ lórí?

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 10:09:07

Mimojuto awn ọmọde ti nnkan bi ounjẹ tabi omi tabi nnkan miran ba sa pa lori tabi ko si lọfun jẹ ara ipenija ti ọpọ awọn obi maa n ni.

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 14:16:57

Àkójọpọ̀ àwọn ìròyìn Ko ṣee ma gbọọ

Agbébọn tún ṣọṣẹ́ ni Plateau, dènà pa èèyàn mẹ́rìnlá àti ọlọ́pàá kan

Agbébọn tún ṣọṣẹ́ ni Plateau, dènà pa èèyàn mẹ́rìnlá àti ọlọ́pàá kan

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 11:56:33

Ṣaaju ni ikọlu akọkọ to pa ọlọpaa ti waye lọjọ naa, ki ikeji ti araalu mẹrinla ti dero ọrun too waye ni nnkan bii aago mẹrin irọlẹ, gẹgẹ bi iroyin ṣe fidi ẹ mulẹ.

Ooni Ogunwusi ti kọ̀ǹgọ́ bọ̀lù níbi Àjọ̀dún ìlú Ayangalu ní Ile Ife

Ooni Ogunwusi ti kọ̀ǹgọ́ bọ̀lù níbi Àjọ̀dún ìlú Ayangalu ní Ile Ife

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 09:36:06

Wọn gbe ajọdun naa kalẹ lati fi ilu kona mọ ọrọ iṣọkan, alaafia ati igbeleke aṣa.

Emir ìlú Gusau, Ibrahim Bello jade láyé lẹ́ni ọdún 71

Emir ìlú Gusau, Ibrahim Bello jade láyé lẹ́ni ọdún 71

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 08:24:19

Owurọ oni, ọjọ Ẹti, ọjọ kẹẹẹdọgbọn, oṣu Keje ọdun 2025 ni iroyin ṣo pe Emir Ibrahim Bello dagbere faye niluu Abuja, lẹyin aisan ọlọjọ pipẹ.

Ilé ẹjọ̀ pàṣẹ pé kí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá san mílíọ̀nù mẹ́wàá Naira fún àwọn olùwọ́de END SARS.

Ilé ẹjọ̀ pàṣẹ pé kí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá san mílíọ̀nù mẹ́wàá Naira fún àwọn olùwọ́de END SARS.

Ọjọ́ Ẹtì, 25 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 06:44:27

Miliọnu mẹwaa naira naa duro fun titẹ ẹtọ awọn olufẹhonu han to n ṣeranti ọdun kẹrin ti iwọde END SARS waye, mọlẹ labẹ ofin.

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀jọ̀gbọ́n Nentawe Yilwatda, alága tuntun fún ẹgbẹ́ APC

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀jọ̀gbọ́n Nentawe Yilwatda, alága tuntun fún ẹgbẹ́ APC

Ọjọ́bọ, 24 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 16:16:59

Nibi ipade igbimọ alaṣẹ APC ẹlẹẹkẹrinla iru ẹ to waye lonii Ọjọbọ niluu Abuja ni wọn ti kede Ọjọgbọn Yilwatda gẹgẹ bi alaga tuntun.

Fídíò ìdúnù ẹbí kan tó jàjà rí ìyẹ̀fun oúnjẹ gbà di ìlúmọ̀ọ́ká lórí ayélujára

Fídíò ìdúnù ẹbí kan tó jàjà rí ìyẹ̀fun oúnjẹ gbà di ìlúmọ̀ọ́ká lórí ayélujára

Ọjọ́bọ, 24 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 13:35:12

Fidio naa lọpọ ti ri bayii gẹgẹbi apẹrẹ ipo ti iyan de duro lara awọn eeyan Gaza.

Ìlù bàrà tí wọ́n lù mí nílé Keu ló mú mi yí ẹ̀sìn mi padà - Peller

Ìlù bàrà tí wọ́n lù mí nílé Keu ló mú mi yí ẹ̀sìn mi padà - Peller

Ọjọ́bọ, 24 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 12:43:09

Peller lo sọ ọrọ yii lasiko to n ba awọn ololufẹ rẹ sọrọ lori ayelujara ti ọkan ninu wọn si pe e ni Musulumi.

Orílẹ̀èdè UK náà ti kéde àdínkù owó ìrànwọ́ sílẹ̀ òkèèrè, báwo ni yóò ṣe kàn Afirika?

Orílẹ̀èdè UK náà ti kéde àdínkù owó ìrànwọ́ sílẹ̀ òkèèrè, báwo ni yóò ṣe kàn Afirika?

Ọjọ́bọ, 24 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 06:04:26

Ajọ Bond to n ri si ọrọ iranwọ silẹ okeere ni UK sọ pe awọn obinrin atawọn ọmọde to n gbe lawọn awujọ tawọn ti ko rọwọ họri pọ si ni yoo fara kaaṣa adinku eto iranwọ UK silẹ okeere naa julọ.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

‘Mo lè kú nítorí àpò ìyẹ̀fun kan ṣoṣo’: Àwọn olùgbé Gaza sọ̀rọ̀ lórí ebi tó ń pa wọ́n, àjọ UN ní ẹgbẹ̀rún kan èèyàn lebí ti lù pa

'Mo lè kú nítorí àpò ìyẹ̀fun kan ṣoṣo': Àwọn olùgbé Gaza sọ̀rọ̀ lórí ebi tó ń pa wọ́n, àjọ UN ní ẹgbẹ̀rún kan èèyàn lebí ti lù pa

Ọjọ́rú, 23 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 13:28:16

Awọn eeyan ti ebi ti fi ọwọ ba ti wọn si ti ru hangogo ti pọ, airi ounjẹ naa n gbilẹ si i, bẹẹ ni awọn eeyan n ku pupọ nitosi awọn agbegbe ti wọn ti n lọ gba ounjẹ iranlọwọ ti ajọ alaanu n pin.

Ẹ̀yin oníṣẹ̀ṣe, ẹ má fi àkókò yín ṣòfò lọ sílé ẹjọ́ lórí ìsìnkú Awujale - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun

Ẹ̀yin oníṣẹ̀ṣe, ẹ má fi àkókò yín ṣòfò lọ sílé ẹjọ́ lórí ìsìnkú Awujale - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun

Ọjọ́rú, 23 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 19:03:29

Ní ọjọ́ Kẹtàlá, oṣù Keje, ọdún 2025 ni ọba Adetona darapọ̀ mọ́ àwọn babańlá rẹ̀ tí wọ́n sì sin-ín ní ìlànà ẹ̀sìn Islam èyí tó fa awuyewuye káàkiri ilẹ̀ Yorùbá.

Gómìnà Seyi Makinde ṣàbẹ̀wò sí ẹbí Olubadan, ṣàlàyé bí ọ̀rọ̀ oyè Ibadan yóò ṣe rí láàrín àádọ́ta ọdún

Gómìnà Seyi Makinde ṣàbẹ̀wò sí ẹbí Olubadan, ṣàlàyé bí ọ̀rọ̀ oyè Ibadan yóò ṣe rí láàrín àádọ́ta ọdún

Ọjọ́rú, 23 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 10:59:44

Lásìkò tí gómìnà Makinde ṣe àbẹ̀wò ìbánikẹ́dùn sí ilé Olubadan ilẹ̀ Ibadan tó wájà, Ọba Owolabi Olakulehin lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, ọjọ́ Kejìlélógún, oṣù Keje, ọdún 2025 ló sọ̀rọ̀ náà.

Ẹ yọ orúkọ mi kúrò lára àwọn afurasí tí wọ́n ń wá torí mi kìí ṣe ọ̀daràn - Sunday Igboho

Ẹ yọ orúkọ mi kúrò lára àwọn afurasí tí wọ́n ń wá torí mi kìí ṣe ọ̀daràn - Sunday Igboho

Ọjọ́rú, 23 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 07:24:17

Igboho sọrọ yii lasiko to ṣabẹwo si Olugbon ti Orile Igbon, Ọba Francis Alao, ni aafin rẹ lọjọ Iṣẹgun ọjọ kejilelogun oṣu Keje yii.

Kí ló mú kí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo wó ìlúmọ̀ọ́ká Ilé ìtura De-Castle Inn ní Ibadan?

Kí ló mú kí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo wó ìlúmọ̀ọ́ká Ilé ìtura De-Castle Inn ní Ibadan?

Ọjọ́rú, 23 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 08:36:54

Ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlogun oṣu Keje ọdun 2025 yii ni ijọba ipinlẹ Oyo gbe awọn katakata ti wọn fi n wole lọ si ile igbafẹ yii.

Lóòtọ́ lèròǹgbà wà láti lọ sí APC tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n èmi àti PDP ti lẹ̀pọ̀, a sì ti gbà láti ti Ààrẹ Tinubu lẹ́yìn fún sáà kejì – Gómìnà Ademola Adeleke

Lóòtọ́ lèròǹgbà wà láti lọ sí APC tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n èmi àti PDP ti lẹ̀pọ̀, a sì ti gbà láti ti Ààrẹ Tinubu lẹ́yìn fún sáà kejì – Gómìnà Ademola Adeleke

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 22 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 13:28:23

Gomina Adeleke ni wọn gba lati ti Tinubu lẹyin gẹgẹbi ọmọ ipinlẹ Ọṣun.

Ohun tí ìwé òfin Naijiria sọ lórí ọ̀rọ̀ Kemi Badenoch tó ní àwọn ọmọ òun kò lànfàání láti di ọmọ Naijiria

Ohun tí ìwé òfin Naijiria sọ lórí ọ̀rọ̀ Kemi Badenoch tó ní àwọn ọmọ òun kò lànfàání láti di ọmọ Naijiria

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 22 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 15:18:41

Kemi fi Naijiria ṣe apẹẹrẹ wi pe loootọ loun jẹ ọmọ Naijiria tori nibẹ lawọn obi oun ti wa, ṣugbọn awọn ọmọ toun bi si UK ko lanfaani lati jẹ ọmọ Naijiria tori oun jẹ obinrin.

Wo ìpínlẹ̀ 31 tí ọ̀rọ̀ ìdásílẹ̀ wọn tó wà níwájú ilé aṣòfin àpapọ̀ Nàìjíríà ń fún ọ̀pọ̀ ní ìrètí

Wo ìpínlẹ̀ 31 tí ọ̀rọ̀ ìdásílẹ̀ wọn tó wà níwájú ilé aṣòfin àpapọ̀ Nàìjíríà ń fún ọ̀pọ̀ ní ìrètí

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 22 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 07:19:14

Igbimọ to n ri si atunṣe iwe ofin Naijiria nile lo ṣe agbekalẹ aba fun idasilẹ ipinlẹ mọkanlelọgbọn ọhun.

Sẹ́nétọ̀ Natasha fi ẹsẹ̀ rìn wọ ilé aṣòfin l’Abuja lẹ́yìn tí àwọn agbófinró dá ọkọ̀ rẹ̀ padà

Sẹ́nétọ̀ Natasha fi ẹsẹ̀ rìn wọ ilé aṣòfin l'Abuja lẹ́yìn tí àwọn agbófinró dá ọkọ̀ rẹ̀ padà

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 22 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 12:41:19

Awọn ẹṣọ ati agbofinro da ọkọ ayọkẹlẹ alawọ dudu ti Natasha wa ninu rẹ duro, bakan naa ni wọn da ọkọ to wa niwaju rẹ duro.

Lójú mi báyìí ni ọ̀rẹ́ mi tik ú, mo ń wòó bí bàlúù náà ṣe gba orí rẹ̀’: akẹ́kọ̀ọ́ ṣàlàyé bí bàlúù iléeṣẹ́ ọmọogun ṣe j alu iléẹ̀kọ̀ọ́ rẹ̀

Lójú mi báyìí ni ọ̀rẹ́ mi tik ú, mo ń wòó bí bàlúù náà ṣe gba orí rẹ̀': akẹ́kọ̀ọ́ ṣàlàyé bí bàlúù iléeṣẹ́ ọmọogun ṣe j alu iléẹ̀kọ̀ọ́ rẹ̀

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 22 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 11:58:14

Ileeṣẹ ologun sọ ninu atẹjade ti wọn fi sita loju opo Facebook wọn pe nnkankan lo bajẹ ninu baalu ileeṣẹ ọmọgun naa lẹyin ti o gbera tan.

Ṣé lóòótọ́ ni Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l’Abuja ti buwọ́ lu ìdásílẹ̀ ìpínlẹ̀ tuntun 31? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ṣé lóòótọ́ ni Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja ti buwọ́ lu ìdásílẹ̀ ìpínlẹ̀ tuntun 31? Ohun tí a mọ̀ rèé

Ọjọ́ Àìkú, 20 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 16:48:50

Agbẹnusọ ile igbimọ naa, Yemi Adaramodu, ṣapejuwe iroyin naa bii ofege ati awuruju.

Wọ́n fẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí kan ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn nítorí ó ṣèwọ́dé tako ìjọba

Wọ́n fẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí kan ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn nítorí ó ṣèwọ́dé tako ìjọba

Ọjọ́ Ajé, 21 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 15:13:20

Yatọ si eyi, wọn tun fi ẹsun nini nnkan ija oloro lọwọ lọna aitọ kan ajafẹtọọ ọmọniyan naa.

Àrẹ̀mọ Saudi tó wà ní ẹsẹ̀ kan àye, ẹsẹ̀ kan ọ̀run fún ogún ọdun ti jáde láyé

Àrẹ̀mọ Saudi tó wà ní ẹsẹ̀ kan àye, ẹsẹ̀ kan ọ̀run fún ogún ọdun ti jáde láyé

Ọjọ́ Àìkú, 20 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 09:28:24

Ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlogun, oṣu Keje ọdun 2025 ni Arẹmọ Alwaleed ku lẹni ọdun marundinlogoji, (35), lẹyin to ti wa nipo aimọ nnkan kan fun ogun ọdun.

'’Mo kábàmọ́ọ̀ pé mo fi ọdún 35 ayé mi ṣiṣẹ́ ọlọ́pàá, N1.4m ni mo rí gbà fún owó ìfẹ̀yìntì’’

''Mo kábàmọ́ọ̀ pé mo fi ọdún 35 ayé mi ṣiṣẹ́ ọlọ́pàá, N1.4m ni mo rí gbà fún owó ìfẹ̀yìntì''

Ọjọ́ Ajé, 21 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 09:55:07

Gẹgẹ bi wọn ṣe wi, Iya awọn ifẹhonuhan alalaafia, (Mother of all peaceful protests) ni wọn pe e .

Ṣé lóòótọ́ ni Muhammed ọmọ Babangida kọ̀ láti gba ipò tí Tinubu fún un? Àlàyé rèé

Ṣé lóòótọ́ ni Muhammed ọmọ Babangida kọ̀ láti gba ipò tí Tinubu fún un? Àlàyé rèé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 22 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 07:04:44

Bawọn kan ṣe n kan saara si Muhammed lawọn kan n bu ẹnu ẹtẹ lu u lori iroyin naa to sọ pe ọ kọ lati gba ipo ti aarẹ Naijiria yan an si.

‘Ifá kọ́ la fi n yan Awujale ilẹ̀ Ìjẹ̀bú, bá ṣe n ṣe rèé’

'Ifá kọ́ la fi n yan Awujale ilẹ̀ Ìjẹ̀bú, bá ṣe n ṣe rèé'

Ọjọ́ Ẹtì, 18 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 14:07:07

Alaye lori bi wọn ṣe n yan Awujalẹ ilẹ Ijẹbu.

Àwọn oníṣẹ̀ṣe yarí nípìnlẹ̀ Ogun, wọ́n ní àwọn n lọ sílé ẹ̀jọ́ lẹ́yìn tí wọ́n lé wọ̀n níbi ìsìnkú Awujalẹ

Àwọn oníṣẹ̀ṣe yarí nípìnlẹ̀ Ogun, wọ́n ní àwọn n lọ sílé ẹ̀jọ́ lẹ́yìn tí wọ́n lé wọ̀n níbi ìsìnkú Awujalẹ

Ọjọ́bọ, 17 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 05:43:54

Ọjọ Aiku, ọjọ kọkanla, oṣu Keje, ọdun 2025 yii ni Awujale lọ darapọ mọ awọn babanla rẹ ti ọpọ eeyan kaakiiri agbaye si ṣedaro ori adẹ ọhun.

Òkúta olówo iyebíye tó jàbọ̀ láti ojú ọ̀run Mars sórílẹ̀ ayé di títà ní $4.3m

Òkúta olówo iyebíye tó jàbọ̀ láti ojú ọ̀run Mars sórílẹ̀ ayé di títà ní $4.3m

Ọjọ́ Ẹtì, 18 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 05:50:26

Ní ẹkùn kan ní orílẹ̀ èdè Niger ni wọ́n ti ṣàwárí òkúta náà nínú oṣù Kọkànlá ọdún 2023.

Àlàfo wo ni ikú Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Muhammadu Buhari yóò fi sí agbo òṣèlú ní Naijiria?

Àlàfo wo ni ikú Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Muhammadu Buhari yóò fi sí agbo òṣèlú ní Naijiria?

Ọjọ́rú, 16 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 09:26:29

Ọpọ eeyan lo fẹran Muhammadu Buhari fun iwa rere ati ijolootọ rẹ, paapaa lapa ariwa Naijiria.

Ọmọ ni mo jẹ́ fún Ooni Ile Ife láéláé, Deji ìlú Akure ṣàlàyé

Ọmọ ni mo jẹ́ fún Ooni Ile Ife láéláé, Deji ìlú Akure ṣàlàyé

Ọjọ́ Ajé, 21 Oṣù Agẹmọ 2025 ní 05:52:54

Deji ilu Akure sọrọ yii nibi ayẹyẹ ọdun kẹwaa rẹ lori apeere awọn baba rẹ lopin ọsẹ to kọja.