Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 19:52:16
Robert Prevost ni Popu akọkọ lati orilẹede Amẹrika, bi o tilẹ jẹ wi pe ọpọlọpọ eeyan lo tun n fi oju ara ilẹ Larin Amerika wo o.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 18:17:18
Lọjọbọ ni wọn kede orukọ Robert Prevost gẹgẹ niẹni ti yoo maa dari ijọ naa lẹyin ipapoda Popoe Francis.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 13:10:17
Aarẹ Amẹrika ana naa sọrọ lori erongba rẹ nipa Aarẹ Donald Trump to wa lori alefa lọwọ.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 12:47:23
BBC Yorùbá kàn sí méjì nínú àwọn ẹbí àwọn èèyàn méje tí wọn jí gbé náà, tí wọn sì ṣàlàyé bí aáyan wọn láti gba ìdásílẹ̀ àwọn èèyàn wọn lọ́wọ́ ajínigbéc, ṣe já sí pàbó.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 12:44:48
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri Nàìjíríà tí kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 08:34:46
Èéfín dúdú ló jáde lálẹ́ àná ní Sinistine Chapel tí ètò ìdìbò náà ti ń wáyé, tí èyí sì túmọ̀ sí pé àwọn cardinal náà kò ì fẹnukò lórí ẹni tó máa di póòpù tuntun.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 11:03:54
Ikọ̀ ti Usman, tí Alex Otti àti Peter Obi faramọ́, ti fún Abure ní ọjọ́ méjì láti yé pe ara rẹ̀ ní alága ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Party mọ́ nítorí sáà rẹ̀ ti parí.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 06:54:17
Ipade ti wọn maa n ṣe lati yan olori ijọ Aguda tuntun naa lo n waye lẹyin isin Novemdiales, eyi ti wọn ṣe lati tọrọ isinmi ayeraye fun Poopu Francis to di oloogbe.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 10:07:09
Abajade nipa ohun to fa a ti baalu to gbe Herbert Wigwe ati ẹbi rẹ fi ja, lo wa ninu atẹjade abọ iwadii ti ajọ to n se akoso eto irina ni Amẹrika gbe jade.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:40:46
Ẹlẹrii yii jẹ oṣiṣẹ DSS. Ọkunrin naa fi awọn ẹri to n kede ibi ti Kanu ti n fun awọn kan laṣẹ lati ba Naijiria ja, han.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 08:42:56
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Kano, SP Abdullahi Haruna Kiyawa ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Faraw ni ijọba Tarauni nipinlẹ Kano.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 11:01:03
Agbẹnus fun ajọ NIMC ni idasilẹ oju opo NIN Auth yoo pese aabo fun awọn iroyin nipa araalu, ti ọpọ ẹka ijọba yoo si jẹ anfani rẹ.
Ọjọ́bọ, 8 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 05:36:45
Ọpọ eeyan lo ti n foju sọna si ibo ni agbaye ti Pope tuntun yoo ti wa.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 12:45:37
Awọn olujẹjọ maraarun ti wọn fi ẹsun ipaniyan naa kan, to fi mọ Alfa Abdulrahman, ni wọn farahan ni ile ẹjọ naa.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 08:34:46
Èéfín dúdú ló jáde lálẹ́ àná ní Sinistine Chapel tí ètò ìdìbò náà ti ń wáyé, tí èyí sì túmọ̀ sí pé àwọn cardinal náà kò ì fẹnukò lórí ẹni tó máa di póòpù tuntun.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 11:35:15
Pat Utomi sọ pé àwọn ṣàgbékalẹ̀ ìjọba òdìkejì náà tó pe orúkọ rẹ̀ ní “Big Tent Coalition Shadow Government” lórí ayélujára.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 10:12:40
Ọkan lara awọn ọmọ Oloogbe, DSP Wale Ogunyẹmi ṣe alaye fun BBC Yoruba pe lati bii oṣu meloo kan sẹyin ni Oloye Ogunyẹmi ti n ṣe aisan.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:20:19
Jaha ni awọn ohun ija to wa lọwọ awọn agbebọn Boko Haram ju eyi to wa lọwọ awọn ọmọ Ologun Naijiria lọ.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 07:10:18
BBC Yorùbá lọ sílẹ̀ Benin láti mọ ìdí tí ìjọba ilẹ̀ náà ṣe kéde ojúlówó ọba mẹ́rìndínlógún péré nínú ọba méjìlélọ́gọ́rin àti ìhà táwọn ọba wọn gba adé lórí wọn kọ sí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ọjọ́rú, 7 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 05:26:23
Iyabo Ojo salaye pe ilẹ Gẹẹsi loun wa, ti EFCC fi ke si oun amọ ọjọ karun un, oṣu Karun un yii gan ni oun to yọju si EFCC nigba ti oun pada de si Naijiria.
Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 08:45:39
Gẹ́gẹ́ bí JAMB ṣe sọ, nínú èèyàn 1,955,069 tó ṣe ìdánwò náà, àwọn tó lé ní ìlàjì ni kò gba tó máàkì 200.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 05:46:01
Igba mẹta ni iru igbeyawo yii maa n waye lọdun nile ijọsin yii lasiko ọdun Ajinde, ninu oṣu Kẹsan an ati oṣu Kejila.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:10:51
Awọn aisan miran wa ti ko ni Ie pa ọmọ ikoko, ṣugbọn ko ni Ie jẹ ki wọn dagba, rin tabi sọrọ.
Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 16:12:14
Jonathan lo sọ ọrọ naa ni ilu bibi rẹ, Otuoke, to wa nipinlẹ Bayelsa.
Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:44:08
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà ní lẹ́yìn tí àwọn ti parí ètò ẹ̀kọ́ àwọn ni àjọ tó ń rí sí ẹ̀yáwó fáwọn akẹ́kọ̀ọ́, Nigeria Education Loan Fund, NELFUND ṣẹ̀ṣẹ̀ ń san owó fáwọn ilé ẹ̀kọ́ àwọn.
Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 05:29:31
Ẹni ogun ọdun ni Audrey Backeberg nigba to kuro nile niluu Reedsburg lọjọ keje, oṣu Keje, ọdun 1962.
Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 15:05:50
Awọn ọmọ ẹgbẹ alatako orilẹede naa ti sọ pe igbesẹ ọhun ko ṣẹyin akitiyan ijọba lati ri daju pe Gnassingbé ko fi ipo silẹ lailai.
Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 10:14:56
Gbígbé oúnjẹ sínú ẹ̀rọ a-mú-oúnjẹ-gbóná (microwave) ní àwọn ipa kan tó máa ń ní lórí ìlera èèyàn pàápàá látara àwọn oúnjẹ tí èèyàn ń gbé sínú ẹ̀rọ yìí.
Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 12:03:56
Abílékọ Modupe Olopade Popoola ṣàlàyé àwọn ìlàkàkà tó dojúkọ gẹ́gẹ́ bí ẹni tó ní àìsàn Sickle Cell nígbà tó ń dàgbà.
Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 07:39:53
Ọjọ́ Kẹrìndínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹrin ni wọ́n bá òkú Tamilore nínú yàrá rẹ̀ nígbà tí àwọn ọlọ́pàá já ilẹ̀kùn àbáwọlé rẹ̀.
Ọjọ́ Àìkú, 4 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:15:43
Aworan jade ni ọjọ diẹ sẹyin ti Trump kede pe o wu oun lati di Pope.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 13:53:30
Ire oko to to miliọnu lọna aadọta naira (50m) ni wọn lo bajẹ.
Ọjọ́bọ, 23 Oṣù Bélú 2023 ní 10:30:33
Asthma le jẹ aisan to lagbara lootọ ṣugbọn pẹlu itọju to peye, eeyan le gbe igbe aye alaafia pẹlu rẹ.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 6 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 06:16:17
Lẹyin ti kootu ba ti dajọ iku fun eeyan tan, ohun to ku ni ki gomina ipinlẹ naa buwọ lu iwe idajọ iku naa.
Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 17:29:53
Eeyan 45,287 ni Russia padanu sinu ogun naa lọdun ọhun nikan ṣoṣo.
Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 10:34:49
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ṣalaye ni awọn ọlọpaa lo kọkọ de ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye, kawọn Amotekun to de bii ologun lori ọkada.
Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 11:10:33
Dele Oyewale sọ fún BBC lọ́jọ́ Ajé pé àwọn kan ló kọ̀wé ẹ̀sùn tako VDM ránṣẹ́ sí àwọn láwọn fi nawọ́ gán an.
Ọjọ́ Ajé, 5 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 08:53:54
Gẹgẹ bi ajọ EFCC to n gbogun ti iwa ibajẹ ati fifi abuku kan naira ṣe ṣalaye, iwa to lodi sofin Banki apapọ Naijiria ni lati maa ta owo naira.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 08:10:41
Idaji Ọjọ Ẹti ni ijamba ina naa ṣẹlẹ
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 10:35:22
Olùjẹ́rìí kan tó pé ara à rẹ ní AAA sọ èyí nígbà tó ń dáhùn ìbéèrè lọ́wọ́ agbẹjọ́rò Nnamdi Kanu, Kanu Agabi.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 09:47:23
Gẹgẹ bi igbimọ olupẹjọ ti ṣalaye, ni nnkan bi ago meje alẹ ni wọn fipa ba Bamise lopọ ti wọn si tun ṣeku pa a lopopona Lekki-Ajah ati afara Carter Bridge.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 17:37:59
Ọrọ naa lo jẹyọ latari ọrọ to n lọ nipa ibaṣepọ rẹ pẹlu Wasiu Ayinde Marshal, ti ọpọ mọ si K1 De Ultimate.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 16:12:47
Gẹgẹ bi ẹka naa ṣe ṣalaye, owo itanran ti i ṣe ẹgbẹrun lọna ogun Riyal, ( 20,000 riyal) owo ilu naa ni ẹni to ba lufin yii yoo san.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 3 Oṣù Ẹ̀bibi 2025 ní 16:33:04
Amofin Yomi Aliu (SAN) sọ fun BBC Yoruba wi pe ofin to mu egungun naa lo mu ẹlẹha, eyi to tumọ si pe bawọn aṣofin ba le kuro ninu ẹgbẹ oṣelu to gbe wọn wọle ibo darapọ mọ ẹgbẹ mii to wu wọn, ko si nnkan to da awọn gomina naa duro lati ṣe bẹẹ.