world-service-rss

BBC News Yorùbá

Ó ti di èèwọ̀ láti máa san owó ìtúsílẹ̀ fún ajínígbé tàbí bá agbésùnmọ̀mí dúnàdúrà – Christopher Musa

Ó ti di èèwọ̀ láti máa san owó ìtúsílẹ̀ fún ajínígbé tàbí bá agbésùnmọ̀mí dúnàdúrà – Christopher Musa

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 19:44:28

Ninu lẹta ti Tinubu fi ṣọwọ si aarẹ ile aṣofin agba l’Abuja, Sẹnẹtọ Godswill Akpabio, fun ibuwọlu ni aarẹ ti ṣalaye pe Musa ni yoo rọpo Alhaji Mohammed Badaru Abubakar minisita eto aabo tẹlẹ to kọwe fipo silẹ lọjọ Aje.

Báǹkì àgbà ilẹ̀ wa, CBN, mú àdínkù bá owó gbígbà síta

Báǹkì àgbà ilẹ̀ wa, CBN, mú àdínkù bá owó gbígbà síta

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:08:30

Igbesẹ tuntun yii ni yoo wọgile eyi to ti wa ni ilẹ tẹlẹ, to fun awọn araalu ni anfani lati gba owo toto milọnu marun un sita lọsẹ, ti awọn ileeṣẹ si le gba milọnu mẹwaa sita.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 12:13:02

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ọba Famodun kì í ṣe ọba ìlú Igbajo, agbára ní Oyetola lò lé wa lórí -Àwọn afọbajẹ

Ọba Famodun kì í ṣe ọba ìlú Igbajo, agbára ní Oyetola lò lé wa lórí -Àwọn afọbajẹ

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:39:44

‎Oloye Olalekan Ogunmoyede, ẹni to jẹ olori awọn afọbajẹ iluu Igbajọ ba BBC news Yoruba sọrọ lori awọ to da rogbodiyan silẹ niluu naa.

Kí ló dé tí ìjọba US ṣe fẹ́ dènà físà àwọn ọmọ Naijiria kan, òṣìṣẹ́ ìjọba àti ẹbí wọn?

Kí ló dé tí ìjọba US ṣe fẹ́ dènà físà àwọn ọmọ Naijiria kan, òṣìṣẹ́ ìjọba àti ẹbí wọn?

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 07:41:08

Akọwe ijọba, Marco Rubio ni pe ile ijọba Washington n gbe igbesẹ yii lori aṣẹ Aarẹ Trump lati gbe ogun ti awọn eeyan kan ti wọn lọwọ ninu kiko ogun ja ati iṣekupani awọn Kristẹni ni Naijiria ati kaakiri agbaye.”

Ìjọba kéde fífi òfin de lílo ojú òpó ayélujára fáwọn ọmọdé tí ọjọ́ orí wọn wà lábẹ́ ọdún mẹ́rìndínlógún, ìdí rèé

Ìjọba kéde fífi òfin de lílo ojú òpó ayélujára fáwọn ọmọdé tí ọjọ́ orí wọn wà lábẹ́ ọdún mẹ́rìndínlógún, ìdí rèé

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:54:42

Ìjọba Australia ní ìgbésẹ̀ fífi òfin de àwọn ojú òpó yìí, èyí tí ọ̀pọ̀ àwọn obí faramọ́, jẹ́ ojúnà láti mú àdínkù bá ìpèníjà táwọn ọmọdé ń kojú lójú òpó ayélujára

Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Edo ní kí ìyàwó Tuface, Natasha Osawaru, wáá ṣàlàyé ara rẹ̀, ìdí rèé

Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Edo ní kí ìyàwó Tuface, Natasha Osawaru, wáá ṣàlàyé ara rẹ̀, ìdí rèé

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:22:44

Natasha ti ifẹ oun ati Tuface gbode lojiji, ni aṣofin to n ṣoju ẹkun Egor, nipinlẹ Edo.

Àwọn ajínigbé fún ìlú ní ọ̀sẹ̀ kan láti san 300m owó ìtúsílẹ̀ àwọn tí wọ́n jí gbé, tàbí kí wọ́n padà wá láti pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ aráàlú

Àwọn ajínigbé fún ìlú ní ọ̀sẹ̀ kan láti san 300m owó ìtúsílẹ̀ àwọn tí wọ́n jí gbé, tàbí kí wọ́n padà wá láti pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ aráàlú

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:53:23

Ko tan si bẹ o, ṣe ni wọn tun fun ilu naa ni gbendeke ọsẹ kan lati san owo yii tabi ki wọn pa gbogbo awọn ti wọn ji gbe.

Kí ló fà á tí ọ̀nà Circular Road n’Ibadan tó yẹ kó mú inú aráàlú dùn ṣe ń gba omijé lójú wọn?

Kí ló fà á tí ọ̀nà Circular Road n'Ibadan tó yẹ kó mú inú aráàlú dùn ṣe ń gba omijé lójú wọn?

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:30:05

Ọpọ awọn olugbe ijọba ibilẹ mẹfa ni ilu Ibadan, olu ilu Ipinlẹ Oyo ni wọn fi ehonu han loni ọjọ Aje ọjọ kẹwaa oṣu kọkonla ọdun 2025 lori bi ijọba Ipinlẹ Oyo se n wo dukia won lulẹ.

Kókó àbájáde ìwádìí àwọn aṣòfin Amẹrika lórí ọ̀rọ̀ tí Trump sọ pé ìpanirun àwọn Kristẹ́nì ń ṣẹlẹ̀ ní Naijiria

Kókó àbájáde ìwádìí àwọn aṣòfin Amẹrika lórí ọ̀rọ̀ tí Trump sọ pé ìpanirun àwọn Kristẹ́nì ń ṣẹlẹ̀ ní Naijiria

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:16:30

Brian Mast to n ri sọrọ ilẹ okeere sọ pe ko si nnkan to jọ ija ileto kan si omiran ninu nnkan to n ṣẹlẹ ni Naijiria bayii, Mast ni awọn to n ṣe ikọlu yii mọọmọ fẹ pawọn kristẹni run lori ilẹ ati nile wọn ni.

Iye ìgbà tí Sowore ti dèrò àtìmọ́lé lẹ́yìn tó gbéná wojú ìjọba Naijiria

Iye ìgbà tí Sowore ti dèrò àtìmọ́lé lẹ́yìn tó gbéná wojú ìjọba Naijiria

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 12:58:06

Ile ẹjọ giga kan niluu Abuja ti sọ pe oun yoo wọgile beeli to fun Omoyele Sowore to ba tun pada sọ ọrọ ti wọn gbagbọ pe o le da omi alaafia Naijiria ru.

Ijó, ayọ̀ báwọn èèyàn 38 tí wọ́n jí gbé ní Eruku ṣe padà sílé

Ijó, ayọ̀ báwọn èèyàn 38 tí wọ́n jí gbé ní Eruku ṣe padà sílé

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:52:57

Irọlẹ oni, ọjọ Aiku, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kọkanla ọdun 2025 ni Aarẹ Tinubu kede bẹẹ loju opo X rẹ.

Ìjọba kéde fífi òfin de lílo ojú òpó ayélujára fáwọn ọmọdé tí ọjọ́ orí wọn wà lábẹ́ ọdún mẹ́rìndínlógún, ìdí rèé

Ìjọba kéde fífi òfin de lílo ojú òpó ayélujára fáwọn ọmọdé tí ọjọ́ orí wọn wà lábẹ́ ọdún mẹ́rìndínlógún, ìdí rèé

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:54:42

Ìjọba Australia ní ìgbésẹ̀ fífi òfin de àwọn ojú òpó yìí, èyí tí ọ̀pọ̀ àwọn obí faramọ́, jẹ́ ojúnà láti mú àdínkù bá ìpèníjà táwọn ọmọdé ń kojú lójú òpó ayélujára

Igun PDP kan kéde Adebayo Adedamola gẹ́gẹ́ bíi olùdíje gómìnà l’Osun

Igun PDP kan kéde Adebayo Adedamola gẹ́gẹ́ bíi olùdíje gómìnà l'Osun

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:33:53

Gomina Ademola Adeleke ko tii kede ẹgbẹ oṣelu ti yoo darapọ mọ bayii, lẹyin to fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.

Ọkùnrin tó jí ara rẹ̀ gbé láti gba owó lọ́wọ́ mọ̀lẹ́bí rẹ̀ l’Ondo dèrò àtìmọ́lé

Ọkùnrin tó jí ara rẹ̀ gbé láti gba owó lọ́wọ́ mọ̀lẹ́bí rẹ̀ l'Ondo dèrò àtìmọ́lé

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:45:47

Mathew Ekele ni ọwọ tẹ niluu Ogbese to wa loju ọna marosẹ ilu Akure siluu Owo.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp

Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59

Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

PDP fi ìwé ẹ̀rí yíyọ kúrò nínú ẹgbẹ́ ránṣẹ́ sí Wike, Fayose àti àwọn yòókù

PDP fi ìwé ẹ̀rí yíyọ kúrò nínú ẹgbẹ́ ránṣẹ́ sí Wike, Fayose àti àwọn yòókù

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 07:27:25

Bẹẹ ba gbagbe, ẹgbẹ oṣelu PDP, lọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kọkanla lasiko ipade apero, fọwọ osi juwe ile fun Wike ati awọn yooku lori ẹsun pe wọn n ditẹ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.

Olórí ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò kú sí àhámọ́ lẹ́yìn oṣù kan

Olórí ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò kú sí àhámọ́ lẹ́yìn oṣù kan

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:05:48

Anicet Ekane to ku si ahamọ yii jẹ ọkan lara awọn to ṣe atileyin fun Issa Tchiroma Bakary, alatako Aarẹ Paul Biya, ninu ibo to wa ye loṣu Kẹwaa ọdun yii.

Ogbomoso Parapo: Bí ìgbẹ́jọ́ láàárín Soun àtàwọn aláṣẹ ẹgbẹ́ ṣe lọ rèé

Ogbomoso Parapo: Bí ìgbẹ́jọ́ láàárín Soun àtàwọn aláṣẹ ẹgbẹ́ ṣe lọ rèé

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:18:04

Ilé ẹjọ́ tún ṣe ìdádúró àwọn aláṣẹ fìdíẹ́ tí Ọba Ghandi yàn láti yé pe ara wọn ní aláṣẹ ẹgbẹ́ náà títí tí ìgbẹ́jọ́ fi máa wáyé ní oṣù Kìíní ọdún 2026.

Kí ló fà á tí Owa ìlú Igbajo fi pé méjì èyí tó fa rògbòdìyàn lẹ́yìn ìpapòdà Ọba Famodun?

Kí ló fà á tí Owa ìlú Igbajo fi pé méjì èyí tó fa rògbòdìyàn lẹ́yìn ìpapòdà Ọba Famodun?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 14:27:10

Eni ọdun mẹtadinlaadọrun ni Ọba Famodun ko to jade laye.

Igun PDP kan kéde Adebayo Adedamola gẹ́gẹ́ bíi olùdíje gómìnà l’Osun

Igun PDP kan kéde Adebayo Adedamola gẹ́gẹ́ bíi olùdíje gómìnà l'Osun

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:33:53

Gomina Ademola Adeleke ko tii kede ẹgbẹ oṣelu ti yoo darapọ mọ bayii, lẹyin to fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.

Ó ti di èèwọ̀ láti máa san owó ìtúsílẹ̀ fún ajínígbé tàbí bá agbésùnmọ̀mí dúnàdúrà – Christopher Musa

Ó ti di èèwọ̀ láti máa san owó ìtúsílẹ̀ fún ajínígbé tàbí bá agbésùnmọ̀mí dúnàdúrà – Christopher Musa

Ọjọ́bọ, 4 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 19:44:28

Ninu lẹta ti Tinubu fi ṣọwọ si aarẹ ile aṣofin agba l’Abuja, Sẹnẹtọ Godswill Akpabio, fun ibuwọlu ni aarẹ ti ṣalaye pe Musa ni yoo rọpo Alhaji Mohammed Badaru Abubakar minisita eto aabo tẹlẹ to kọwe fipo silẹ lọjọ Aje.

“Ẹ wo bí ẹ̀rí èké tí mo jẹ́ nílé ẹjọ́ ṣe sọ ọ̀dọ́ mẹ́ta tí kò lẹ́ṣẹ̀ lọ́rùn dèrò ẹ̀wọ̀n ódún 36”

"Ẹ wo bí ẹ̀rí èké tí mo jẹ́ nílé ẹjọ́ ṣe sọ  ọ̀dọ́ mẹ́ta tí kò lẹ́ṣẹ̀ lọ́rùn dèrò ẹ̀wọ̀n ódún 36"

Ọjọ́rú, 3 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 06:14:42

Bishop ni niṣe loun n gbọn nigba ti wọn ni koun wa jẹrii nile ẹjọ tori nnkan ti ko ṣẹlẹ ni wọn sọ pe koun maa sọ.

Tinubu ní kí wọ́n dáàbò bo olùdíje sípò Ààrẹ Guinea-Bissau ní ọọ́físì ìjọba Naijiria lẹ́yìn ìdìtẹ̀gbàjọba ológun

Tinubu ní kí wọ́n dáàbò bo olùdíje sípò Ààrẹ Guinea-Bissau ní ọọ́físì ìjọba Naijiria lẹ́yìn ìdìtẹ̀gbàjọba ológun

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:19:58

Ninu lẹta kan ti minisita to n ri si ọrọ ilẹ okeere, Yusuf Tuggar, buwọlu, eyii to fi ṣọwọ si Aarẹ ẹgbẹ Ecowas, Omar Touray, Tuggar ni Aarẹ Naijiria ti paṣe pe ki wọn gbalejo ọkunrin naa ni ọọfisi ijọba Naijiria to wa lorilẹede naa, ki wọn si tun daabo bo nibẹ.

Ìwakùsà lọ́nà àìtọ́ ló ń ṣokùnfà ètò àbò tó mẹ́hẹ lọ́dọ̀ wa, a fẹ́ kí Ààrẹ gbẹ́sẹ̀le – Àwọn gómìnà Àríwá

Ìwakùsà lọ́nà àìtọ́ ló ń ṣokùnfà ètò àbò tó mẹ́hẹ lọ́dọ̀ wa, a fẹ́ kí Ààrẹ gbẹ́sẹ̀le – Àwọn gómìnà Àríwá

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:36:31

Ipade naa ti awọn ori ade agbegbe naa yọju si ni wọn ti fẹnuko pe ki wọn maa ko owo ti iye rẹ to biliọnu kan naira jọ loṣoṣu fun eto abo agbegbe naa.

Ṣé ọmọ bíbí lè dín iye ọjọ́ tó yẹ kí obìnrin lò lókè eèpẹ̀ kù?

Ṣé ọmọ bíbí lè dín iye ọjọ́ tó yẹ kí obìnrin lò lókè eèpẹ̀ kù?

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 08:19:54

Iwadii kan ti fi han pe bi eeyan ṣe n bi ọmọ si le maa yọ oṣu mẹfa lara obinrin.

Àkójọpọ̀ ìkọlù tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria lẹ́yìn tí Tinubu kéde ìlú ò fararọ lẹ́ka ètò ààbò

Àkójọpọ̀ ìkọlù tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria lẹ́yìn tí Tinubu kéde ìlú ò fararọ lẹ́ka ètò ààbò

Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 2 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 06:06:37

Orilẹede Naijiria n koju oniruuru ipenija lọwọ yii latari oriṣiiriṣii ikọlu tawọn janduku agbebọn n ṣe kaakiri papaa julọ lẹkun ariwa orilẹede yii.

Àwọn agbébọn tún ṣèkọlù sí Eruku ní Kwara, jí àgbẹ̀ kan gbé lọ lẹ́yìn ìkọlù ilé ìjọ́sìn CAC

Àwọn agbébọn tún ṣèkọlù sí Eruku ní Kwara, jí àgbẹ̀ kan gbé lọ lẹ́yìn ìkọlù ilé ìjọ́sìn CAC

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 14:15:36

Ni ana ọjọ Aiku ni iṣẹlẹ yii waye ni ilu naa, o si jẹ ẹlẹẹkeji iru ẹ ninu osu Kọkanla ọdun yii.

Ẹ wo bí onírúurú ẹbí ṣe ń fi okòwò tata rán àwọn ọmọ wọn nílé ẹ̀kọ́, gbọ́ bùkátà

Ẹ wo bí onírúurú ẹbí ṣe ń fi okòwò tata rán àwọn ọmọ wọn nílé ẹ̀kọ́, gbọ́ bùkátà

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 07:54:11

Ṣiṣe odẹ tata ti wọn maa n pe ni Mungwin ni ede Cameroon jẹ nnkan to ti di aṣa nilẹ naa, o si jẹ ọrọ aje fun ọpọ eeyan níbẹ.

Orúkọ àwọn aṣojú Naijiria sílẹ̀ òkèèrè ti Tinubu fi ránṣẹ́ sí àwọn aṣòfin di ariwo

Orúkọ àwọn aṣojú Naijiria sílẹ̀ òkèèrè ti Tinubu fi ránṣẹ́ sí àwọn aṣòfin di ariwo

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 13:16:48

Ọpọ lo n sọ pe Aarẹ Tinubu fi orukọ awọn eeyan naa ranṣẹ lati san oore ti wọn ṣe fun un lọna kan tabi ikeji pada ni.

Àwọn ajínigbé jí Ọba gbé ní Kwara, bèèrè N150m owó ìtúsílẹ̀

Àwọn ajínigbé jí Ọba gbé ní Kwara, bèèrè N150m owó ìtúsílẹ̀

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:37:07

Nnkan bi ago mẹsan an abọ owurọ ọjọ Satide ni iṣẹlẹ naa waye lasiko ti Oba, Ojibara ti ilu Bayangan, Alhaji Kamilu Salami n lọ sinu oko rẹ.

Agbébọn jí obìnrin tó fẹ́ ṣe ìgbéyàwó láàárọ̀ òní, ọ̀rẹ́ rẹ̀, àtàwọn mẹ́jọ míì gbé lọ

Agbébọn jí obìnrin tó fẹ́ ṣe ìgbéyàwó láàárọ̀ òní, ọ̀rẹ́ rẹ̀, àtàwọn mẹ́jọ míì gbé lọ

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 10:08:27

Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpee ipinlẹ naa, DSP Ahmad Rufa’i, to fidi iroyin naa mulẹ fun ileeṣẹ iroyin Channels ni awọn ti gbe igbesẹ lọri ikọlu ọhun.

Ọmọ Amẹrika ni mí ṣùgbọ́n nítorí olólùfẹ́ mi Aanuoluwapo ni mo ṣe lọ kọ́ èdè Yoruba - Pablo

Ọmọ Amẹrika ni mí ṣùgbọ́n nítorí olólùfẹ́ mi Aanuoluwapo ni mo ṣe lọ kọ́ èdè Yoruba - Pablo

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 09:42:49

Lati ọdun méjọ ti awọn mejeji fẹ ara wọn l’Amẹrika ni wọn pinnu lati wa si Naijiria.

Abẹ ìsẹjọba rẹ gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ni ìgbésùnmọ̀mí ti bẹ̀rẹ̀- Iléeṣẹ́ Ààrẹ fèsì padà fún Obasanjo

Abẹ ìsẹjọba rẹ gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ni ìgbésùnmọ̀mí ti bẹ̀rẹ̀- Iléeṣẹ́ Ààrẹ fèsì padà fún Obasanjo

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 11:32:24

Obasanjo fi aidunnu rẹ lori bi eto aabo ṣe n buru sii ni Nàìjíríà, ààrẹ Naijiria tẹlẹ ni awọn ọmọ Naijiria lẹtọọ lati bèèrè iranwọ ilẹ okeere lẹyìn tí ìjọba ti kuna lati daabo bo araalu.

Ṣé lóòótọ́ ní ayẹta Yorùbá wà, àwọn wo ló le lò ó, kí ni èèwọ̀ rẹ̀ àti ìdí tó fi lè kùnà? 

Ṣé lóòótọ́ ní ayẹta Yorùbá wà, àwọn wo ló le lò ó, kí ni èèwọ̀ rẹ̀ àti ìdí tó fi lè kùnà? 

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 12:01:00

BBC Yoruba kan si awọn oníṣẹṣe Yoruba lati mọ boya lootọ ni ayẹta wa, ta le lo pese ayẹta ati idi to fi le kùnà.

WHO kéde ìlànà tuntun láti kojú ìṣòro àìrí ọmọ bí

WHO kéde ìlànà tuntun láti kojú ìṣòro àìrí ọmọ bí

Ọjọ́ Ajé, 1 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2025 ní 04:31:03

WHO ní ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́ tí àwọn lọ́kọláya tó bá ń kojú ìṣòro àìrí ọmọ bí nílò láti ṣe ni lílọ sí ilé ìwòsàn fún àyẹ̀wò tó péye.

Àwọn jàndùkú agbébọn tún ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Kerubu (C&S) ní Kogi, jí pásítọ̀ àti ìyàwó rẹ̀ pẹ̀lú àwọn èèyàn míì gbé lọ

Àwọn jàndùkú agbébọn tún ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Kerubu (C&S) ní Kogi, jí pásítọ̀ àti ìyàwó rẹ̀ pẹ̀lú àwọn èèyàn míì gbé lọ

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 17:05:53

A gbọ wi pe ṣadeedee lawọn janduku agbebọn ọhun ya wọ ṣoọṣi C & S naa ti wọn si bẹrẹ sii yinbọn lera lera.

Chelsea v Arsenal: Àwọn nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yìí

Chelsea v Arsenal: Àwọn nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yìí

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 11:03:20

Arsenal ti bori ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ninu meje ti wọn ti gba ni ligi, ti Chelsea si ti bori marun ninu mẹfa.

Ìkọ́ aláàbò dóòlà ọ̀dọ́bìnrin méjìlá tí ajínigbé jí gbé ní Borno

Ìkọ́ aláàbò dóòlà ọ̀dọ́bìnrin méjìlá tí ajínigbé jí gbé ní Borno

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 10:52:50

Eyi waye ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ologun fi lede loju opo ayelujara wọn lọgbọn ọjọ oṣu kọkanla ọdun 2025.

Èèyàn tó lé ní 70,000 ni Israel ti pa ní Gaza – Hamas

Èèyàn tó lé ní 70,000 ni Israel ti pa ní Gaza – Hamas

Ọjọ́ Àìkú, 30 Oṣù Bélú 2025 ní 09:05:27

Ogun aarin awọn mejeji bẹrẹ lẹyin ti Hamas gbẹmi awọn ọmọ Israle lọjọ keje, oṣu Kẹwaa, ọdun 2023.